Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
b Bíbélì sọ ìgbà méjì ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ táwọn ọmọ Ísírẹ́lì fi ẹran rúbọ sí Jèhófà ní aginjù. Ìgbà àkọ́kọ́ ni ìgbà tí wọ́n yan àwọn àlùfáà, ìgbà kejì sì ni ìgbà tí wọ́n ń ṣe Ìrékọjá. Ìgbà méjèèjì yìí sì jẹ́ lọ́dún 1512 Ṣ.S.K., ìyẹn ọdún kejì lẹ́yìn tí wọ́n kúrò ní Íjíbítì.—Léf. 8:14–9:24; Nọ́ń. 9:1-5.