Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
d Ọba Ásà dá àwọn ẹ̀ṣẹ̀ tó burú gan-an. (2 Kíró. 16:7, 10) Síbẹ̀, Bíbélì sọ pé ó ṣe àwọn nǹkan tó dáa lójú Jèhófà. Bó tiẹ̀ jẹ́ pé nígbà tí wòlíì Jèhófà kọ́kọ́ bá a wí, kò gbà, àmọ́ ó jọ pé nígbà tó yá, ó ronú pìwà dà. Àwọn nǹkan tó dáa tó ṣe lójú Jèhófà ju àwọn àṣìṣe ẹ̀ lọ. Ó hàn gbangba pé Jèhófà nìkan ni Ásà jọ́sìn, ó sì ṣe gbogbo ohun tó lè ṣe láti mú ìbọ̀rìṣà kúrò nílẹ̀ náà.—1 Ọba 15:11-13; 2 Kíró. 14:2-5.