Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
b ÀLÀYÉ Ọ̀RỌ̀: Nínú Bíbélì, tí wọ́n bá lo ọ̀rọ̀ náà “ẹ̀ṣẹ̀,” ohun tí wọ́n ń sọ ni kéèyàn ṣe nǹkan tí ò dáa, bíi kó jalè, kó ṣèṣekúṣe tàbí kó pààyàn. (Ẹ́kís. 20:13-15; 1 Kọ́r. 6:18) Àmọ́ láwọn ibì kan nínú Bíbélì, “ẹ̀ṣẹ̀” ni àìpé tá a jogún nígbà tí wọ́n bí wa, bó tiẹ̀ jẹ́ pé a ò tíì dẹ́ṣẹ̀ kankan.