ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ

Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé

a Nínú Bíbélì, ọ̀rọ̀ tí wọ́n túmọ̀ sí “ìràpadà” máa ń tọ́ka sí iye kan tàbí ohun iyebíye kan tẹ́nì kan san. Bí àpẹẹrẹ, ọ̀rọ̀ Hébérù náà ka·pharʹ túmọ̀ sí “bò.” (Jẹ́nẹ́sísì 6:14) Ó sábà máa ń tọ́ka sí bíbo ẹ̀ṣẹ̀. (Sáàmù 65:3) Ọ̀rọ̀ míì tó jẹ mọ́ ọn ni koʹpher, ohun tíyẹn máa ń tọ́ka sí ni iye tí wọ́n san láti bo ẹ̀ṣẹ̀ ẹnì kan tàbí tú u sílẹ̀. (Ẹ́kísódù 21:30) Bákan náà, ọ̀rọ̀ Gíríìkì náà lyʹtron sábà máa ń túmọ̀ sí “ìràpadà,” wọ́n sì lè túmọ̀ rẹ̀ sí “owó ìtúsílẹ̀.” (Mátíù 20:28; Bíbélì The New Testament in Modern Speech, by R.  F.  Weymouth) Àwọn òǹkọ̀wé tó jẹ́ Gíríìkì máa ń lo ọ̀rọ̀ náà tí wọ́n bá ń tọ́ka sí owó tẹ́nì kan san kí wọ́n lè tú ẹrú sílẹ̀ tàbí ra ẹni tí wọ́n mú lẹ́rú nígbà ogun pa dà.

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́