Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
a Bíbélì lo ọ̀rọ̀ náà “irú,” tí ìtumọ̀ rẹ̀ gbòòrò ju “oríṣi” bí àwọn onímọ̀ sáyẹ́ǹsì ti ṣe máa ń lò ó. Lọ́pọ̀ ìgbà, táwọn onímọ̀ sáyẹ́ǹsì bá sọ pé oríṣi ohun alààyè tuntun kan ti hú yọ, ohun tó máa ń jẹ́ ni pé irú míì lára ìṣẹ̀dá tó ti wà tẹ́lẹ̀ ni wọ́n ń pè ní ohun tuntun. Ìwé Jẹ̀nẹ́sísì sì lo ọ̀rọ̀ náà “irú” láti fi èyí hàn.