ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • Apa 1
    Tẹ́tí sí Ọlọ́run
    • Apa 1

      Bíbélì ni Ọlọ́run fi ń bá wa sọ̀rọ̀. 2 Tímótì 3:16

      Ibi gbogbo ni àwọn èèyàn ti ń tẹ́tí sí Ọlọ́run. Mátíù 28:19

  • Apa 2
    Tẹ́tí sí Ọlọ́run
    • Apa 2

      Jèhófà ló dá ohun gbogbo tó wà ní ọ̀run . . . àti lórí ilẹ̀ ayé. Sáàmù 83:18; Ìfihàn 4:11

  • Apa 3
    Tẹ́tí sí Ọlọ́run
    • Apa 3

      Àìmọye nǹkan rere ni Jèhófà fún Ádámù àti Éfà. Jẹ́nẹ́sísì 1:28

      Ọlọ́run sọ pé wọn kò gbọ́dọ̀ jẹ èso ọ̀kan lára àwọn igi tó wà nínú ọgbà náà. Jẹ́nẹ́sísì 2:16, 17

  • Apa 4
    Tẹ́tí sí Ọlọ́run
    • Apa 4

      Ádámù àti Éfà ṣàìgbọràn sí Ọlọ́run, wọ́n sì kú. Jẹ́nẹ́sísì 3:6, 23

      Àwọn tó ti kú dà bí erùpẹ̀ lásán. Jẹ́nẹ́sísì 3:19

  • Apa 5
    Tẹ́tí sí Ọlọ́run
    • Apa 5

      Ìwà burúkú ni àwọn èèyàn tó pọ̀ jù nígbà ayé Nóà ń hù. Jẹ́nẹ́sísì 6:5

      Nóà tẹ́tí sí Ọlọ́run, ó sì kan ọkọ̀ áàkì. Jẹ́nẹ́sísì 6:13, 14, 18, 19, 22

  • Apa 2
    Tẹ́tí sí Ọlọ́run
    • Apa 2

      Ọlọ́run pa àwọn èèyàn burúkú yẹn run, àmọ́ ó dá Nóà àti ìdílé rẹ̀ sí. Jẹ́nẹ́sísì 7:11, 12, 23

      Ọlọ́run ṣì tún máa pa àwọn ẹni burúkú run, á sì dá àwọn ẹni rere sí. Mátíù 24:37-39

  • Apa 7
    Tẹ́tí sí Ọlọ́run
    • Apa 7

      Jèhófà rán Jésù wá sí ayé. 1 Jòhánù 4:9

      Ohun rere ni Jésù ṣe, àmọ́ àwọn èèyàn kórìíra rẹ̀. 1 Pétérù 2:21-24

  • Apa 8
    Tẹ́tí sí Ọlọ́run
    • Apa 8

      Jésù kú torí ká lè ní ìyè. Jòhánù 3:16

      Ọlọ́run jí Jésù dìde, ó sì sọ ọ́ di Ọba Ìjọba Ọlọ́run. Dáníẹ́lì 7:13, 14

  • Apa 9
    Tẹ́tí sí Ọlọ́run
    • Apa 9

      Àwọn wàhálà tó ń ṣẹlẹ̀ nínú ayé jẹ́ ká mọ̀ pé Ìjọba Ọlọ́run máa tó dé. Lúùkù 21:10, 11; 2 Tímótì 3:1-5

      Ìjọba Ọlọ́run máa mú gbogbo ìwà ibi kúrò. 2 Pétérù 3:13

  • Apa 10
    Tẹ́tí sí Ọlọ́run
    • Apa 2

      Ọlọ́run máa jí èyí tó pọ̀ jù lára àwọn tó ti kú dìde sí ayé. Ìṣe 24:15

      Ìjọba Ọlọ́run máa fòpin sí gbogbo ìyà tó ń jẹ aráyé. Ìfihàn 21:3, 4

  • Apa 11
    Tẹ́tí sí Ọlọ́run
    • Apa 11

      Ó dájú pé Ọlọ́run máa ń gbọ́ àdúrà wa. 1 Pétérù 3:12

      A lè mẹ́nu kan ọ̀pọ̀ nǹkan nínú àdúrà wa. 1 Jòhánù 5:14

  • Apa 12
    Tẹ́tí sí Ọlọ́run
    • Apa 12

      Ìfẹ́ ló máa jẹ́ kí ìdílé ní ayọ̀. Éfésù 5:33

      Ẹ jẹ́ onínúure àti olóòótọ́, ẹ má ṣe ya ọ̀dájú, ẹ má sì jẹ́ aláìṣòótọ́. Kólósè 3:5, 8-10

  • Apa 13
    Tẹ́tí sí Ọlọ́run
    • Apa 13

      Máa sá fún ohun tó burú. 1 Kọ́ríńtì 6:9, 10

      Máa ṣe ohun tó dára. Mátíù 7:12

  • Apa 14
    Tẹ́tí sí Ọlọ́run
    • Apa 14

      Ọ̀dọ̀ Ọlọ́run ni kí o dúró sí. 1 Pétérù 5:6-9

      Yan ohun tí ó tọ́, ìyẹn ni pé kí o tẹ́tí sí Ọlọ́run. Mátíù 7:24, 25

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́