-
Ìrìn Àjò Láti Íjíbítì Sí Ilẹ̀ ÌléríWo “Ilẹ̀ Dáradára” Náà
-
-
Lẹ́yìn èyí, Mósè kó Ísírẹ́lì gba ibi tí àwọn òkè ńláńlá wà níhà gúúsù lọ́hùn-ún, wọ́n sì pàgọ́ sí Òkè Sínáì. Ibẹ̀ làwọn èèyàn Ọlọ́run ti gba Òfin, tí wọ́n kọ́ àgọ́ ìjọsìn, tí wọ́n sì rú àwọn ẹbọ. Ní ọdún kejì, wọ́n kọrí sí ìhà àríwá wọ́n sì la “aginjù ńlá àti amúnikún-fún-ẹ̀rù” kọjá, ìrìn àjò wọn sí àgbègbè Kádéṣì (Kadeṣi-báníà) yóò sì gbà tó ọjọ́ mọ́kànlá gbáko. (Di 1:1, 2, 19; 8:15) Nítorí pé àwọn èèyàn náà bẹ̀rẹ̀ sí í bẹ̀rù nítorí ìròyìn burúkú tí àwọn amí mẹ́wàá mú wá, wọ́n dẹni tó ń rìn káàkiri fún odindi ọdún méjìdínlógójì. (Nu 13:1-14:34) Lára àwọn ibi tí wọ́n ti dúró ni Ábúrónà àti Esioni-gébérì, lẹ́yìn náà ni wọ́n tún ṣẹ́rí padà sí Kádéṣì.—Nu 33:33-36.
-
-
Ìrìn Àjò Láti Íjíbítì Sí Ilẹ̀ ÌléríWo “Ilẹ̀ Dáradára” Náà
-
-
F8 Òkè Sínáì (Hórébù)
F8 AGINJÙ SÍNÁÌ
F7 Kiburoti- hátááfà
G7 Hásérótì
G6 Rimoni-pérésì
G5 Rísà
G3 Kádéṣì
G3 Bẹne-jáákánì
G5 Hoori-hágígádì
GB5 Jótíbátà
GB5 Ábúrónà
GB6 Esioni-gébérì
G3 Kádéṣì
-