ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • “Ojú Àánú Ọlọ́run Wa”
    Sún Mọ́ Jèhófà
    • 10 Àpẹẹrẹ kan lohun tó ṣẹlẹ̀ nígbà ayé Jẹ́fútà. Jèhófà jẹ́ káwọn ọmọ Ámónì fìyà jẹ àwọn ọmọ Ísírẹ́lì fún ọdún méjìdínlógún torí pé wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí í bọ òrìṣà. Nígbà tó yá, àwọn ọmọ Ísírẹ́lì ronú pìwà dà. Bíbélì sọ pé: “Wọ́n wá kó àwọn ọlọ́run àjèjì kúrò láàárín wọn, wọ́n sì ń sin Jèhófà, débi pé ojú rẹ̀ ò gbà á mọ́ bí Ísírẹ́lì ṣe ń jìyà.”b (Àwọn Onídàájọ́ 10:6-16) Nígbà táwọn èèyàn Jèhófà fi hàn pé àwọn ti ronú pìwà dà látọkàn wá, ojú rẹ̀ ò gbà á mọ́ kí ìyà ṣì máa jẹ wọ́n. Torí náà Ọlọ́run yọ́nú sáwọn ọmọ Ísírẹ́lì, ó sì fún Jẹ́fútà lágbára láti gbà wọ́n lọ́wọ́ àwọn ọ̀tá wọn.​—Àwọn Onídàájọ́ 11:30-33.

  • “Ojú Àánú Ọlọ́run Wa”
    Sún Mọ́ Jèhófà
    • b Gbólóhùn náà “ojú rẹ̀ ò gbà á mọ́” tún lè túmọ̀ sí pé kò lè ṣe sùúrù mọ́. Bíbélì Tanakh​—A New Translation of the Holy Scriptures túmọ̀ rẹ̀ sí pé: “Kò lè fara dà á mọ́ kí ìyà máa jẹ Ísírẹ́lì.”

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́