ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • Àpèjúwe Àwọn Òṣìṣẹ́ Ọgbà Àjàrà
    Jésù—Ọ̀nà, Òtítọ́ Àti Ìyè
    • “Ìjọba ọ̀run dà bíi baálé ilé kan tó jáde lọ ní àárọ̀ kùtù láti gba àwọn òṣìṣẹ́ sínú ọgbà àjàrà rẹ̀. Lẹ́yìn tó bá àwọn òṣìṣẹ́ náà ṣàdéhùn pé òun máa fún wọn ní owó dínárì kan fún ọjọ́ kan, ó ní kí wọ́n lọ sínú ọgbà àjàrà òun. Ó tún jáde ní nǹkan bíi wákàtí kẹta, ó sì rí àwọn míì tí wọ́n dúró ní ibi ọjà, tí wọn ò ríṣẹ́ ṣe; ó sọ fún wọn pé, ‘Ẹ̀yin náà, ẹ lọ sínú ọgbà àjàrà, màá sì fún yín ní ohunkóhun tó bá tọ́.’ Torí náà, wọ́n lọ. Ó tún jáde ní nǹkan bíi wákàtí kẹfà àti wákàtí kẹsàn-án, ó sì ṣe ohun kan náà. Níkẹyìn, ní nǹkan bíi wákàtí kọkànlá, ó jáde lọ, ó sì rí àwọn míì tí wọ́n dúró, ó sọ fún wọn pé, ‘Kí ló dé tí ẹ dúró síbí látàárọ̀, tí ẹ ò ríṣẹ́ ṣe?’ Wọ́n sọ fún un pé, ‘Torí kò sẹ́ni tó gbà wá síṣẹ́ ni.’ Ó sọ fún wọn pé, ‘Ẹ̀yin náà, ẹ lọ sínú ọgbà àjàrà.’”—Mátíù 20:1-7.

  • Àpèjúwe Àwọn Òṣìṣẹ́ Ọgbà Àjàrà
    Jésù—Ọ̀nà, Òtítọ́ Àti Ìyè
    • “Ìjọba ọ̀run dà bíi baálé ilé kan tó jáde lọ ní àárọ̀ kùtù láti gba àwọn òṣìṣẹ́ sínú ọgbà àjàrà rẹ̀. Lẹ́yìn tó bá àwọn òṣìṣẹ́ náà ṣàdéhùn pé òun máa fún wọn ní owó dínárì kan fún ọjọ́ kan, ó ní kí wọ́n lọ sínú ọgbà àjàrà òun. Ó tún jáde ní nǹkan bíi wákàtí kẹta, ó sì rí àwọn míì tí wọ́n dúró ní ibi ọjà, tí wọn ò ríṣẹ́ ṣe; ó sọ fún wọn pé, ‘Ẹ̀yin náà, ẹ lọ sínú ọgbà àjàrà, màá sì fún yín ní ohunkóhun tó bá tọ́.’ Torí náà, wọ́n lọ. Ó tún jáde ní nǹkan bíi wákàtí kẹfà àti wákàtí kẹsàn-án, ó sì ṣe ohun kan náà. Níkẹyìn, ní nǹkan bíi wákàtí kọkànlá, ó jáde lọ, ó sì rí àwọn míì tí wọ́n dúró, ó sọ fún wọn pé, ‘Kí ló dé tí ẹ dúró síbí látàárọ̀, tí ẹ ò ríṣẹ́ ṣe?’ Wọ́n sọ fún un pé, ‘Torí kò sẹ́ni tó gbà wá síṣẹ́ ni.’ Ó sọ fún wọn pé, ‘Ẹ̀yin náà, ẹ lọ sínú ọgbà àjàrà.’”—Mátíù 20:1-7.

  • Àpèjúwe Àwọn Òṣìṣẹ́ Ọgbà Àjàrà
    Jésù—Ọ̀nà, Òtítọ́ Àti Ìyè
    • Àwọn àlùfáà àtàwọn míì bíi tiwọn gbà pé àwọn yòókù ò ṣiṣẹ́ fún Ọlọ́run tó àwọn, pé wákàtí mélòó kan péré ni wọ́n fi ń ṣiṣẹ́ nínú ọgbà àjàrà Ọlọ́run dípò kí wọ́n ṣiṣẹ́ látàárọ̀ ṣúlẹ̀. Nínú àpèjúwe Jésù, àwọn Júù tó kù yẹn ni Jésù fi wé àwọn ọkùnrin tó bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ “ní nǹkan bíi wákàtí kẹta” (9:00 àárọ̀) tàbí wákàtí kẹfà, wákàtí kẹsàn-án àti níkẹyìn wákàtí kọkànlá (5:00 ìrọ̀lẹ́).

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́