-
Ohun Tó Ń Mú Ọkàn Fà sí ÌṣekúṣeJí!—2013 | May
-
-
“Olúkúlùkù ẹni tí ń bá a nìṣó ní wíwo obìnrin kan láti ní ìfẹ́ onígbòónára sí i, ti ṣe panṣágà pẹ̀lú rẹ̀ ná nínú ọkàn-àyà rẹ̀.”—Mátíù 5:28.
-
-
Ohun Tó Ń Mú Ọkàn Fà sí ÌṣekúṣeJí!—2013 | May
-
-
Bí àpẹẹrẹ, Bíbélì sọpé tí ọkùnrin tó ti gbéyàwó bá ń “bá a nìṣó ní wíwo obìnrin kan” tí kì í ṣe aya rẹ̀, tó sì ń wù ú pé kó bá a lò pọ̀, ó lè mú kó ṣe panṣágà. Ìlànà Bíbélì yìí kan gbogbo ẹni tó ti lọ́kọ tàbí aya àtàwọn tí kò tí ì ṣègbéyàwó. Tó bá ń “bá a nìṣó ní wíwo” àwòrán ìṣekúṣe, tó sì ń wù ú pé kó ní ìbálòpọ̀ tí kò tọ́, ìwà tí inú Ọlọ́run kò dùn sí ló ń hù yẹn.
-