ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • Ìwé Àkàkọ́gbọ́n Tí Ìmọ̀ràn Rẹ̀ Wúlò Lóde Ìwòyí
    Ilé Ìṣọ́—1999 | April 1
    • Nígbà tí Mihoko rí àwọn ìyípadà tí ọkọ rẹ̀ ṣe, òun náà bẹ̀rẹ̀ sí fi ohun tó ń kọ́ sílò. Ìlànà kan tó ṣèrànwọ́ gan-an nìyí: “Ẹ dẹ́kun dídánilẹ́jọ́ kí a má bàa dá yín lẹ́jọ́; nítorí irú ìdájọ́ tí ẹ fi ń dáni lẹ́jọ́, ni a ó fi dá yín lẹ́jọ́.”e Nítorí náà, Mihoko àti ọkọ rẹ̀ pinnu pé àwọn yóò máa sọ̀rọ̀ nípa àwọn ibi táwọn ti ń ṣe dáadáa, àti bí àwọn ṣe lè ṣàtúnṣe ní àwọn ibi yòókù, dípò kí àwọn máa di ẹ̀bi ru ẹnì kìíní kejì. Kí ni ìyọrísí rẹ̀? Mihoko rántí pé: “Ó fún mi láyọ̀ ní ti gidi. A ti ń ṣe èyí nídìí oúnjẹ ní alaalẹ́. Kódà, ọmọkùnrin wa ọlọ́dún mẹ́ta máa ń dá sí ìjùmọ̀sọ̀rọ̀ náà. Ó tù wá lára gan-an!”

  • Ìwé Àkàkọ́gbọ́n Tí Ìmọ̀ràn Rẹ̀ Wúlò Lóde Ìwòyí
    Ilé Ìṣọ́—1999 | April 1
    • e Mátíù 7:1, 2.

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́