ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • O Ṣeyebíye Lójú Ọlọ́run!
    Jí!—1999 | June 8
    • Fún àpẹẹrẹ, nígbà tí Jésù ń ṣàpèjúwe bí ọ̀kọ̀ọ̀kan àwọn ọmọ ẹ̀yìn rẹ̀ ṣe ṣeyebíye tó, ó sọ pé: “Kì í ha ṣe ológoṣẹ́ méjì ni a ń tà ní ẹyọ owó kan tí ìníyelórí rẹ̀ kéré? Síbẹ̀, kò sí ọ̀kan nínú wọn tí yóò jábọ́ lulẹ̀ láìjẹ́ pé Baba yín mọ̀. Ṣùgbọ́n gbogbo irun orí yín gan-an ni a ti kà. Nítorí náà, ẹ má bẹ̀rù: ẹ níye lórí púpọ̀ ju ọ̀pọ̀ ológoṣẹ́ lọ.” (Mátíù 10:29-31) Ronú nípa ohun tí àwọn ọ̀rọ̀ wọ̀nyẹn yóò túmọ̀ sí fún àwọn olùgbọ́ ọ̀rọ̀ Jésù ní ọ̀rúndún kìíní.

  • O Ṣeyebíye Lójú Ọlọ́run!
    Jí!—1999 | June 8
    • Ǹjẹ́ o lóye kókó tó wà nínú àpèjúwe amọ́kànyọ̀ tí Jésù ṣe? Bí Jèhófà bá ka àwọn ẹyẹ kéékèèké pàápàá sí, mélòómélòó ni àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ orí ilẹ̀ ayé yóò ti jẹ́ ẹni ọ̀wọ́n sí i tó! Lójú Jèhófà, kò sí ọ̀kan nínú wa tí kò ní láárí. Olúkúlùkù wa ṣeyebíye gan-an sí Jèhófà débi pé ó ń kíyè sí ohun tó kéré jù lọ lára wa pàápàá—gbogbo irun orí wa ló níye.

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́