ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • Wọ́n “Kún fún Ẹ̀mí Mímọ́”
    “Jẹ́rìí Kúnnákúnná Nípa Ìjọba Ọlọ́run”
    • 16. Báwo làwọn Kristẹni ọgọ́rùn-ún ọdún kìíní ṣe fi hàn pé àwọn lẹ́mìí ìfara-ẹni-rúbọ?

      16 Ó dájú pé Jèhófà bù kún àwọn èèyàn yẹn. Àkọsílẹ̀ náà sọ pé: “Gbogbo àwọn tó di onígbàgbọ́ wà pa pọ̀, wọ́n sì jọ ń lo gbogbo ohun tí wọ́n ní, wọ́n ń ta àwọn ohun ìní àti dúkìá wọn, wọ́n sì ń pín owó tí wọ́n rí níbẹ̀ fún gbogbo wọn, bí ohun tí ẹnì kọ̀ọ̀kan nílò bá ṣe pọ̀ tó.”f (Ìṣe 2:44, 45) Ó dájú pé, gbogbo Kristẹni tòótọ́ ló yẹ kó fara wé ẹ̀mí ìfẹ́ àti ti ìfara-ẹni-rúbọ tí wọ́n ní.

  • Wọ́n “Kún fún Ẹ̀mí Mímọ́”
    “Jẹ́rìí Kúnnákúnná Nípa Ìjọba Ọlọ́run”
    • f Wọ́n ṣètò yìí fún ìgbà díẹ̀ kó lè ṣeé ṣe fáwọn àlejò tó wá sí Jerúsálẹ́mù láti kẹ́kọ̀ọ́ sí i. Ńṣe ni wọ́n fi tinútinú yọ̀ǹda àwọn nǹkan tí wọ́n ní, kì í ṣe pé ẹnikẹ́ni fipá mú wọn.​—Ìṣe 5:1-4.

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́