ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • Ọ̀dọ̀ Ọlọ́run Ni Bíbélì Ti Wá
    Gbádùn Ayé Rẹ Títí Láé!—Ìjíròrò Látinú Bíbélì
    • 2. Ṣe gbogbo èèyàn ni Bíbélì wúlò fún?

      Ọlọ́run sọ pé “gbogbo orílẹ̀-èdè àti ẹ̀yà àti ahọ́n àti èèyàn” ló máa jàǹfààní látinú ọ̀rọ̀ tó wà nínú Bíbélì. (Ka Ìfihàn 14:6.) Ó sì rí bẹ́ẹ̀ lóòótọ́. Torí pé nínú gbogbo ìwé tó wà láyé lóde òní, Bíbélì ló wà ní èdè tó pọ̀ jù lọ! Ó fẹ́rẹ̀ẹ́ jẹ́ pé gbogbo èèyàn ló ní Bíbélì lọ́wọ́ tàbí tí wọ́n ti gbọ́ ọ̀rọ̀ inú ẹ̀ rí, láìka ibi tí wọ́n ń gbé sí tàbí èdè yòówù kí wọ́n máa sọ.

  • Ohun Tó Yẹ Ká Mọ̀ Nípa Àwọn Áńgẹ́lì
    Gbádùn Ayé Rẹ Títí Láé!—Ìjíròrò Látinú Bíbélì
    • Áńgẹ́lì kan ń darí àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà méjì bí wọ́n ṣe ń wàásù láti ilé dé ilé.

      4. Àwọn áńgẹ́lì máa ń ran àwọn èèyàn lọ́wọ́ kí wọ́n lè kẹ́kọ̀ọ́ nípa Jèhófà

      Àwọn áńgẹ́lì kọ́ ló ń wàásù fáwọn èèyàn ní tààràtà. Kàkà bẹ́ẹ̀, ńṣe ni wọ́n máa ń darí àwọn èèyàn Ọlọ́run lọ sọ́dọ̀ àwọn tó bá fẹ́ kẹ́kọ̀ọ́ nípa Ọlọ́run. Ka Ìfihàn 14:6, 7, lẹ́yìn náà kó o dáhùn àwọn ìbéèrè yìí:

      • Kí nìdí tá a fi nílò ìrànlọ́wọ́ àwọn áńgẹ́lì lẹ́nu iṣẹ́ ìwàásù?

      • Ṣé inú ẹ dùn bó o ṣe mọ̀ pé àwọn áńgẹ́lì lè darí ẹ lọ sọ́dọ̀ àwọn tó fẹ́ kẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì? Kí nìdí tó o fi sọ bẹ́ẹ̀?

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́