ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • scl ojú ìwé 15-16
  • Àníyàn

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Àníyàn
  • Àwọn Ẹsẹ Bíbélì Tó Lè Ran Àwa Kristẹni Lọ́wọ́
Àwọn Ẹsẹ Bíbélì Tó Lè Ran Àwa Kristẹni Lọ́wọ́
scl ojú ìwé 15-16

Àníyàn

Ṣé ò ń ṣàníyàn torí pé o ò lówó lọ́wọ́, o ò rí oúnjẹ jẹ tàbí torí pé o ò rílé gbé?

Owe 10:15; 19:7; 30:8

  • Àpẹẹrẹ inú Bíbélì:

    • Ida 3:19—Lẹ́yìn tí wọ́n pa ìlú Jerúsálẹ́mù run, kò síbi tí wòlíì Jeremáyà àtàwọn ọmọ Ísírẹ́lì tó kù á máa gbé

    • 2Kọ 8:1, 2; 11:27—Ìgbà kan wà tó jẹ́ pé òtòṣì paraku làwọn Kristẹni tó wà ní Makedóníà, ọ̀pọ̀ ìgbà ni àpọ́sítélì Pọ́ọ̀lù sì wà láìsí oúnjẹ, aṣọ àti ibùgbé

  • Àwọn ẹsẹ Bíbélì tó lè tù wá nínú:

    • Sm 37:25; 145:15; Owe 10:3; Mt 6:25-34

    • Tún wo Di 24:19

Ṣé ò ń ṣàníyàn torí pé o ò lọ́rẹ̀ẹ́, torí pé o dá wà tàbí torí pé àwọn èèyàn ò fẹ́ràn ẹ?

Job 19:19; Onw 4:10, 12

  • Àpẹẹrẹ inú Bíbélì:

    • 1Ọb 18:22; 19:9, 10—Ìgbà kan wà tí wòlíì Èlíjà ń ṣàníyàn torí ó gbà pé òun nìkan ni ìránṣẹ́ Jèhófà tó jẹ́ olóòótọ́ tó ṣẹ́ kù ní Ísírẹ́lì

    • Jer 15:16-21—Nígbà tí wòlíì Jeremáyà sọ ọ̀rọ̀ Ọlọ́run fáwọn èèyàn, wọn ò tẹ́tí sí i, ṣe ni wọ́n ń ṣàríyá. Ìyẹn sì mú kó máa ṣe wòlíì náà bíi pé òun dá wà

  • Àwọn ẹsẹ Bíbélì tó lè tù wá nínú:

    • Sm 25:15, 16; 1Pe 5:7

  • Àpẹẹrẹ inú Bíbélì tó lè tù wá nínú:

    • 1Ọb 19:1-19—Jèhófà fún wòlíì Èlíjà ní oúnjẹ àti omi, ó fara balẹ̀ tẹ́tí sí i, ó tún jẹ́ kó mọ̀ pé òun lágbára láti ràn án lọ́wọ́

    • Jo 16:32, 33—Jésù mọ̀ pé àwọn ọ̀rẹ́ òun máa pa òun tì, àmọ́ kò ṣàníyàn torí ó dá a lójú pé Jèhófà máa dúró ti òun

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́