ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • nwt ojú ìwé 1268-1269
  • Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Hábákúkù

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Hábákúkù
  • Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • Báwo Ni Àkókò Tó Ṣẹ́ Kù Fún Àwọn Olubi Ti Pọ̀ Tó?
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2000
  • Jèhófà Kò Ní Fi Nǹkan Falẹ̀
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2000
  • Kíkún Fún Ìdùnnú Nínú Ọlọ́run Ìgbàlà Wa
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2000
  • Gbẹ́kẹ̀ Lé Jèhófà Kó O Lè Wà Láàyè!
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa (Ẹ̀dà Tó Wà fún Ìkẹ́kọ̀ọ́)—2018
Àwọn Míì
Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Hábákúkù

HÁBÁKÚKÙ

OHUN TÓ WÀ NÍNÚ ÌWÉ YÌÍ

  • 1

    • Wòlíì náà ké pe Jèhófà pé kó ran òun lọ́wọ́ (1-4)

      • “Jèhófà, báwo ló ṣe máa pẹ́ tó?” (2)

      • ‘Kí nìdí tí o fi fàyè gba ìnilára?’ (3)

    • Ọlọ́run lo àwọn ará Kálídíà láti ṣèdájọ́ (5-11)

    • Wòlíì náà bẹ Jèhófà (12-17)

      • ‘Ọlọ́run mi, ìwọ kì í kú’ (12)

      • ‘O ti mọ́ jù láti máa wo ohun búburú’ (13)

  • 2

    • “Èmi yóò máa ṣọ́nà kí n lè mọ ohun tí yóò sọ” (1)

    • Èsì tí Jèhófà fún wòlíì náà (2-​20)

      • ‘Ṣáà máa retí ìran náà’ (3)

      • Ìṣòtítọ́ yóò mú kí olódodo máa wà láàyè (4)

      • Nǹkan márùn-ún tó mú kí àwọn ará Kálídíà gbé (6-20)

        • Gbogbo ayé yóò ní ìmọ̀ nípa Jèhófà (14)

  • 3

    • Wòlíì náà bẹ Jèhófà pé kó gbé ìgbésẹ̀ (1-19)

      • Ọlọ́run yóò gba àwọn ẹni àmì òróró rẹ̀ là (13)

      • Máa yọ̀ nítorí Jèhófà láìka wàhálà sí (17, 18)

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́