12 Jálẹ̀ àwọn ìran yín, gbogbo ọmọkùnrin tó wà láàárín yín tó jẹ́ ọmọ ọjọ́ mẹ́jọ gbọ́dọ̀ dádọ̀dọ́,*+ bẹ́ẹ̀ náà ni ẹnikẹ́ni tí wọ́n bá bí nínú ilé àti ẹnikẹ́ni tí kì í ṣe ọmọ* yín àmọ́ tí ẹ fi owó yín rà lọ́wọ́ àjèjì.
8 “Ó tún fún Ábúráhámù ní májẹ̀mú ìdádọ̀dọ́,*+ ó sì bí Ísákì,+ ó dádọ̀dọ́ rẹ̀* ní ọjọ́ kẹjọ,+ Ísákì sì bí* Jékọ́bù, Jékọ́bù sì bí àwọn olórí ìdílé* méjìlá (12).