ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • Nọ́ńbà 21:1
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    • 21 Nígbà tí ọba ìlú Árádì+ ti ilẹ̀ Kénáánì, tó ń gbé Négébù gbọ́ pé Ísírẹ́lì ti ń gba ọ̀nà Átárímù bọ̀, ó gbéjà ko Ísírẹ́lì, ó sì kó lára wọn lọ.

  • Nọ́ńbà 21:3
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    • 3 Jèhófà fetí sí ohùn Ísírẹ́lì, ó sì fi àwọn ọmọ Kénáánì lé wọn lọ́wọ́, wọ́n sì pa àwọn àti àwọn ìlú wọn run pátápátá. Wọ́n wá pe orúkọ ibẹ̀ ní Hóómà.*+

  • Diutarónómì 1:44
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    • 44 Àwọn Ámórì tí wọ́n ń gbé ní òkè náà sì jáde wá pàdé yín, wọ́n lé yín dà nù bí oyin ṣe máa ń ṣe, wọ́n sì tú yín ká láti Séírì títí lọ dé Hóómà.

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́