-
Àwọn Onídàájọ́ 6:13Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
-
-
13 Ni Gídíónì bá sọ fún un pé: “Má bínú olúwa mi, tó bá jẹ́ pé Jèhófà wà pẹ̀lú wa, kí ló dé tí gbogbo èyí fi ń ṣẹlẹ̀ sí wa?+ Ibo ni gbogbo àwọn iṣẹ́ ìyanu rẹ̀ wà, èyí tí àwọn bàbá wa ròyìn ẹ̀ fún wa+ pé, ‘Ṣebí Jèhófà ló kó wa kúrò ní Íjíbítì?’+ Jèhófà ti pa wá tì+ báyìí, ó sì ti fi wá lé Mídíánì lọ́wọ́.”
-