35 Mo ti fi hàn yín nínú ohun gbogbo nípa ṣíṣe iṣẹ́ kára lọ́nà yìí+ pé, ẹ gbọ́dọ̀ ṣèrànwọ́ fún àwọn tó jẹ́ aláìlera, ẹ sì gbọ́dọ̀ fi àwọn ọ̀rọ̀ Jésù Olúwa sọ́kàn, nígbà tí òun fúnra rẹ̀ sọ pé: ‘Ayọ̀ púpọ̀ wà nínú fífúnni+ ju èyí tó wà nínú rírígbà lọ.’”