-
Nọ́ńbà 31:27Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
-
-
27 Pín ẹrù tí wọ́n kó bọ̀ láti ogun sí méjì, kí ìdá kan jẹ́ ti àwọn ọmọ ogun tí wọ́n lọ jagun, kí ìdá kejì sì jẹ́ ti gbogbo àwọn yòókù nínú àpéjọ+ náà.
-