ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • 1 Àwọn Ọba 2:10
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    • 10 Lẹ́yìn náà, Dáfídì sinmi pẹ̀lú àwọn baba ńlá rẹ̀, wọ́n sì sin ín sí Ìlú Dáfídì.+

  • 2 Kíróníkà 21:18-20
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    • 18 Lẹ́yìn gbogbo èyí, Jèhófà fi àìsàn kan tí kò ṣeé wò sàn kọ lù ú ní ìfun rẹ̀.+ 19 Nígbà tó yá, tí ọdún méjì gbáko ti kọjá, ìfun rẹ̀ tú jáde nítorí àìsàn tó ń ṣe é, ó sì kú nínú ìrora ńlá tí àìsàn náà mú bá a; àwọn èèyàn rẹ̀ kò ṣe ìfinásun nítorí rẹ̀ bí wọ́n ti ṣe ìfinásun nítorí àwọn baba ńlá rẹ̀.+ 20 Ẹni ọdún méjìlélọ́gbọ̀n (32) ni nígbà tó jọba, ọdún mẹ́jọ ló sì fi ṣàkóso ní Jerúsálẹ́mù. Kò sẹ́ni tí ikú rẹ̀ dùn. Torí náà, wọ́n sin ín sí Ìlú Dáfídì,+ àmọ́ kì í ṣe ní ibi tí wọ́n sin àwọn ọba sí.+

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́