17 “Nítorí náà, ohun tí Jèhófà, Ọlọ́run àwọn ọmọ ogun, Ọlọ́run Ísírẹ́lì sọ nìyí: ‘Wò ó, màá mú gbogbo àjálù tí mo ti kìlọ̀ fún Júdà àti gbogbo àwọn tó ń gbé ní Jerúsálẹ́mù wá sórí wọn,+ torí pé mo ti bá wọn sọ̀rọ̀, ṣùgbọ́n wọn kò fetí sílẹ̀, mo sì ń pè wọ́n, ṣùgbọ́n wọn kò dáhùn.’”+