ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • Nehemáyà 2:19, 20
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    • 19 Nígbà tí Sáńbálátì ará Hórónì àti Tòbáyà + ọmọ Ámónì+ tó jẹ́ òṣìṣẹ́ ọba* pẹ̀lú Géṣémù ọmọ ilẹ̀ Arébíà+ gbọ́ nípa rẹ̀, wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí í fi wá ṣe yẹ̀yẹ́,+ wọ́n sì ń fojú pa wá rẹ́, wọ́n ní: “Kí lẹ̀ ń ṣe yìí? Ẹ fẹ́ ṣọ̀tẹ̀ sí ọba, àbí?”+ 20 Àmọ́, mo fún wọn lésì pé: “Ọlọ́run ọ̀run ni Ẹni tó máa jẹ́ ká ṣàṣeyọrí,+ àwa ìránṣẹ́ rẹ̀ yóò dìde, a ó sì kọ́lé; àmọ́ ẹ̀yin ò ní ìpín kankan, bẹ́ẹ̀ ni ẹ ò ní ẹ̀tọ́ tàbí ìrántí ní Jerúsálẹ́mù.”+

  • Jòhánù 4:9
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    • 9 Obìnrin ará Samáríà náà wá sọ fún un pé: “Báwo ni ìwọ, tí o jẹ́ Júù, ṣe máa ní kí èmi, obìnrin ará Samáríà fún ọ lómi?” (Torí àwọn Júù kì í ní ohunkóhun ṣe pẹ̀lú àwọn ará Samáríà.)+

  • Jòhánù 4:22
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    • 22 Ẹ̀ ń jọ́sìn ohun tí ẹ ò mọ̀;+ àwa ń jọ́sìn ohun tí a mọ̀, torí ọ̀dọ̀ àwọn Júù ni ìgbàlà ti bẹ̀rẹ̀.+

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́