Jẹ́nẹ́sísì 3:19 Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun 19 Inú òógùn ojú rẹ ni wàá ti máa jẹun títí wàá fi pa dà sí ilẹ̀, torí inú rẹ̀ lo ti wá.+ Erùpẹ̀ ni ọ́, ìwọ yóò sì pa dà sí erùpẹ̀.”+ Jẹ́nẹ́sísì 47:9 Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun 9 Jékọ́bù sọ fún Fáráò pé: “Àádóje (130) ọdún ni mo fi ń lọ káàkiri.* Ọdún tí mo ti lò láyé kéré, ó sì kún fún wàhálà,+ kò gùn tó ọdún tí àwọn baba ńlá mi lò láyé nígbà tí wọ́n ń lọ káàkiri.”*+ Sáàmù 90:10 Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun 10 Àádọ́rin (70) ọdún ni gígùn ọjọ́ ayé wa,Tàbí kó jẹ́ ọgọ́rin (80) ọdún+ tí èèyàn bá lókun tó ṣàrà ọ̀tọ̀.* Síbẹ̀, wàhálà àti ìbànújẹ́ ló kún inú wọn;Wọ́n á kọjá lọ kíákíá, a ó sì fò lọ.+ Oníwàásù 2:23 Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun 23 Torí ní gbogbo ọjọ́ ayé rẹ̀, iṣẹ́ rẹ̀ ń mú ìrora àti ìjákulẹ̀ bá a,+ kódà kì í rí oorun sùn lóru.+ Asán ni èyí pẹ̀lú.
19 Inú òógùn ojú rẹ ni wàá ti máa jẹun títí wàá fi pa dà sí ilẹ̀, torí inú rẹ̀ lo ti wá.+ Erùpẹ̀ ni ọ́, ìwọ yóò sì pa dà sí erùpẹ̀.”+
9 Jékọ́bù sọ fún Fáráò pé: “Àádóje (130) ọdún ni mo fi ń lọ káàkiri.* Ọdún tí mo ti lò láyé kéré, ó sì kún fún wàhálà,+ kò gùn tó ọdún tí àwọn baba ńlá mi lò láyé nígbà tí wọ́n ń lọ káàkiri.”*+
10 Àádọ́rin (70) ọdún ni gígùn ọjọ́ ayé wa,Tàbí kó jẹ́ ọgọ́rin (80) ọdún+ tí èèyàn bá lókun tó ṣàrà ọ̀tọ̀.* Síbẹ̀, wàhálà àti ìbànújẹ́ ló kún inú wọn;Wọ́n á kọjá lọ kíákíá, a ó sì fò lọ.+
23 Torí ní gbogbo ọjọ́ ayé rẹ̀, iṣẹ́ rẹ̀ ń mú ìrora àti ìjákulẹ̀ bá a,+ kódà kì í rí oorun sùn lóru.+ Asán ni èyí pẹ̀lú.