-
Jeremáyà 50:20Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
-
-
20 “Ní ọjọ́ yẹn àti ní àkókò yẹn,” ni Jèhófà wí,
“A ó wá ẹ̀bi Ísírẹ́lì kiri,
Ṣùgbọ́n a kò ní rí ìkankan,
A kò sì ní rí àwọn ẹ̀ṣẹ̀ Júdà,
Nítorí màá dárí ji àwọn tí mo jẹ́ kí ó ṣẹ́ kù.”+
-