-
Léfítíkù 14:3, 4Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
-
-
3 Kí àlùfáà lọ sí ẹ̀yìn ibùdó, kó sì yẹ̀ ẹ́ wò. Tí àrùn ẹ̀tẹ̀ náà bá ti lọ lára adẹ́tẹ̀ náà, 4 kí àlùfáà pàṣẹ pé kó mú ààyè ẹyẹ méjì tó mọ́ wá, pẹ̀lú igi kédárì, òwú aláwọ̀ rírẹ̀dòdò àti ewéko hísópù láti fi wẹ̀ ẹ́ mọ́.+
-
-
Hébérù 9:13, 14Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
-
-
13 Torí tí ẹ̀jẹ̀ àwọn ewúrẹ́ àti ti àwọn akọ màlúù+ àti eérú ọmọ màlúù* tí wọ́n fi wọ́n àwọn tó ti di aláìmọ́ bá sọ wọ́n di mímọ́ kó lè wẹ ẹran ara mọ́,+ 14 ǹjẹ́ ẹ̀jẹ̀ Kristi,+ ẹni tó tipasẹ̀ ẹ̀mí àìnípẹ̀kun fi ara rẹ̀ rúbọ sí Ọlọ́run láìní àbààwọ́n kò ní ṣe jù bẹ́ẹ̀ lọ láti wẹ ẹ̀rí ọkàn wa mọ́ kúrò nínú àwọn òkú iṣẹ́,+ ká lè máa ṣe iṣẹ́ ìsìn mímọ́ fún Ọlọ́run alààyè?+
-