1 Àwọn Ọba 8:36 Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun 36 nígbà náà, kí o gbọ́ láti ọ̀run, kí o sì dárí ẹ̀ṣẹ̀ àwọn ìránṣẹ́ rẹ jì wọ́n, ìyẹn àwọn èèyàn rẹ Ísírẹ́lì, nítorí pé wàá tọ́ wọn sí ọ̀nà+ tó yẹ kí wọ́n máa rìn; kí o sì rọ̀jò sórí ilẹ̀ rẹ+ tí o fún àwọn èèyàn rẹ láti jogún. Sáàmù 25:8 Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun 8 Ẹni rere àti adúróṣinṣin ni Jèhófà.+ Ìdí nìyẹn tó fi ń kọ́ àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ ní ọ̀nà tó yẹ kí wọ́n tọ̀.+ Àìsáyà 54:13 Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun 13 Jèhófà máa kọ́ gbogbo àwọn ọmọ* rẹ,+Àlàáfíà àwọn ọmọ* rẹ sì máa pọ̀ gan-an.+ Míkà 4:2 Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun 2 Ọ̀pọ̀ orílẹ̀-èdè máa lọ, wọ́n á sì sọ pé: “Ẹ wá, ẹ jẹ́ ká lọ sórí òkè Jèhófà,Sí ilé Ọlọ́run Jékọ́bù.+ Ó máa kọ́ wa ní àwọn ọ̀nà rẹ̀,A ó sì máa rìn ní àwọn ọ̀nà rẹ̀.” Torí òfin* máa jáde láti Síónì,Ọ̀rọ̀ Jèhófà sì máa jáde láti Jerúsálẹ́mù.
36 nígbà náà, kí o gbọ́ láti ọ̀run, kí o sì dárí ẹ̀ṣẹ̀ àwọn ìránṣẹ́ rẹ jì wọ́n, ìyẹn àwọn èèyàn rẹ Ísírẹ́lì, nítorí pé wàá tọ́ wọn sí ọ̀nà+ tó yẹ kí wọ́n máa rìn; kí o sì rọ̀jò sórí ilẹ̀ rẹ+ tí o fún àwọn èèyàn rẹ láti jogún.
8 Ẹni rere àti adúróṣinṣin ni Jèhófà.+ Ìdí nìyẹn tó fi ń kọ́ àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ ní ọ̀nà tó yẹ kí wọ́n tọ̀.+
2 Ọ̀pọ̀ orílẹ̀-èdè máa lọ, wọ́n á sì sọ pé: “Ẹ wá, ẹ jẹ́ ká lọ sórí òkè Jèhófà,Sí ilé Ọlọ́run Jékọ́bù.+ Ó máa kọ́ wa ní àwọn ọ̀nà rẹ̀,A ó sì máa rìn ní àwọn ọ̀nà rẹ̀.” Torí òfin* máa jáde láti Síónì,Ọ̀rọ̀ Jèhófà sì máa jáde láti Jerúsálẹ́mù.