-
Hósíà 6:11Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
-
-
11 Àmọ́, ìwọ Júdà, a ti dá àkókò ìkórè fún ọ,
Nígbà tí mo bá kó àwọn èèyàn mi tó wà ní oko ẹrú pa dà.”+
-
-
Jóẹ́lì 3:1Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
-
-
3 “Wò ó! ní àwọn ọjọ́ náà àti ní àkókò yẹn,
Nígbà tí mo bá dá àwọn tí wọ́n kó lẹ́rú láti Júdà àti Jerúsálẹ́mù pa dà,+
-