-
Sáàmù 50:3Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
-
-
3 Ọlọ́run wa yóò wá, kò sì ní dákẹ́.+
-
-
Ìsíkíẹ́lì 11:21Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
-
-
21 “‘“Ṣùgbọ́n ní ti àwọn tí ọkàn wọn ṣì ń fà sí àwọn ohun tó ń ríni lára tó sì ń kóni nírìíra tí wọ́n ń ṣe, màá fi ìwà wọn san wọ́n lẹ́san,” ni Jèhófà Olúwa Ọba Aláṣẹ wí.’”
-