ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • Àìsáyà 40:19
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    • 19 Oníṣẹ́ ọnà ṣe ère,*

      Oníṣẹ́ irin fi wúrà bò ó,+

      Ó sì fi fàdákà rọ ẹ̀wọ̀n.

  • Àìsáyà 41:7
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    •  7 Torí náà, oníṣẹ́ ọnà ń fún oníṣẹ́ irin+ lókun;

      Ẹni tó ń fi òòlù irin* lu nǹkan di pẹlẹbẹ

      Ń fún ẹni tó ń fi òòlù lu nǹkan lórí irin lókun.

      Ó ń sọ nípa ohun tí wọ́n jó pọ̀ pé: “Ó dáa.”

      Wọ́n wá fi ìṣó kàn án, kó má bàa ṣubú.

  • Jeremáyà 10:3
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    •  3 Àṣà àwọn èèyàn náà jẹ́ ẹ̀tàn.*

      Igi igbó lásán ni wọ́n gé lulẹ̀,

      Ohun tí oníṣẹ́ ọnà fi irin iṣẹ́* gbẹ́ ni.+

  • Hósíà 8:6
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    •  6 Torí láti Ísírẹ́lì ni èyí ti wá.

      Ohun tí oníṣẹ́ ọnà ṣe ni, kì í ṣe Ọlọ́run;

      Ọmọ màlúù Samáríà yóò di èérún.

  • Ìṣe 17:29
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    • 29 “Nítorí náà, bí a ṣe jẹ́ ọmọ* Ọlọ́run,+ kò yẹ kí a rò pé Olú Ọ̀run rí bíi wúrà tàbí fàdákà tàbí òkúta, bí ohun tí a fi ọgbọ́n àti iṣẹ́ ọnà èèyàn gbẹ́ lére.+

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́