6 “Àmọ́ ìwọ, ọmọ èèyàn, má bẹ̀rù wọn;+ má ṣe jẹ́ kí ọ̀rọ̀ wọn dẹ́rù bà ọ́, bó tilẹ̀ jẹ́ pé ẹ̀gún àti òṣùṣú+ yí ọ ká,* tí o sì ń gbé láàárín àwọn àkekèé. Má ṣe jẹ́ kí ọ̀rọ̀ wọn dẹ́rù bà ọ́,+ má sì jẹ́ kí ojú wọn bà ọ́ lẹ́rù,+ torí ọlọ̀tẹ̀ ilé ni wọ́n.