Àìsáyà 48:8 Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun 8 Rárá, o ò tíì gbọ́,+ o ò tíì mọ̀ ọ́n,Etí rẹ ò sì là nígbà àtijọ́. Nítorí mo mọ̀ pé ọ̀dàlẹ̀ paraku ni ọ́,+A sì ti pè ọ́ ní ẹlẹ́ṣẹ̀ látìgbà tí wọ́n ti bí ọ.+ Hósíà 3:1 Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun 3 Ìgbà náà ni Jèhófà sọ fún mi pé: “Lọ lẹ́ẹ̀kan sí i, nífẹ̀ẹ́ ìyàwó rẹ tí ọkùnrin míì ti fẹ́, tó sì ń ṣe àgbèrè,+ bí Jèhófà ṣe nífẹ̀ẹ́ àwọn èèyàn Ísírẹ́lì+ bí wọ́n tilẹ̀ lọ sọ́dọ̀ àwọn ọlọ́run míì,+ tí wọ́n sì fẹ́ràn ìṣù àjàrà gbígbẹ.”* Hósíà 5:7 Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun 7 Wọ́n ti hùwà àìṣòótọ́ sí Jèhófà,+Torí wọ́n ti bí àwọn ọmọ àjèjì. Ní báyìí, kò ní ju oṣù kan lọ tí àwọn àti ìpín* wọn á fi pa run.
8 Rárá, o ò tíì gbọ́,+ o ò tíì mọ̀ ọ́n,Etí rẹ ò sì là nígbà àtijọ́. Nítorí mo mọ̀ pé ọ̀dàlẹ̀ paraku ni ọ́,+A sì ti pè ọ́ ní ẹlẹ́ṣẹ̀ látìgbà tí wọ́n ti bí ọ.+
3 Ìgbà náà ni Jèhófà sọ fún mi pé: “Lọ lẹ́ẹ̀kan sí i, nífẹ̀ẹ́ ìyàwó rẹ tí ọkùnrin míì ti fẹ́, tó sì ń ṣe àgbèrè,+ bí Jèhófà ṣe nífẹ̀ẹ́ àwọn èèyàn Ísírẹ́lì+ bí wọ́n tilẹ̀ lọ sọ́dọ̀ àwọn ọlọ́run míì,+ tí wọ́n sì fẹ́ràn ìṣù àjàrà gbígbẹ.”*
7 Wọ́n ti hùwà àìṣòótọ́ sí Jèhófà,+Torí wọ́n ti bí àwọn ọmọ àjèjì. Ní báyìí, kò ní ju oṣù kan lọ tí àwọn àti ìpín* wọn á fi pa run.