-
Ìsíkíẹ́lì 25:5Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
-
-
5 Èmi yóò sọ Rábà+ di ibi tí àwọn ràkúnmí á ti máa jẹko, èmi yóò sì sọ ilẹ̀ àwọn ọmọ Ámónì di ibi ìsinmi agbo ẹran; ẹ ó sì wá mọ̀ pé èmi ni Jèhófà.”’”
-
-
Émọ́sì 1:14Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
-
-
14 Torí náà, màá sọ iná sí ògiri Rábà,+
Á sì jó àwọn ilé gogoro rẹ̀ tó láàbò run,
Ariwo á sọ ní ọjọ́ ogun,
Àti ìjì líle ní ọjọ́ ẹ̀fúùfù.
-