ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • Àìsáyà 21:6
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    •  6 Torí ohun tí Jèhófà sọ fún mi nìyí:

      “Lọ, yan aṣọ́nà, kí o sì ní kó ròyìn ohun tó bá rí.”

  • Àìsáyà 21:8
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    •  8 Ó wá ké jáde bíi kìnnìún, ó ní:

      “Jèhófà, orí ilé ìṣọ́ ni mò ń dúró sí nígbà gbogbo ní ọ̀sán,

      Mi ò sì kúrò níbi tí a fi mí ṣọ́ ní gbogbo òru.+

  • Jeremáyà 6:17
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    • 17 “Mo sì yan àwọn olùṣọ́+ tí wọ́n sọ pé,

      ‘Ẹ fetí sí ìró ìwo!’”+

      Àmọ́ wọ́n sọ pé: “A ò ní fetí sí i.”+

  • Ìsíkíẹ́lì 33:7
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    • 7 “Ní tìrẹ, ọmọ èèyàn, mo ti fi ọ́ ṣe olùṣọ́ fún ilé Ísírẹ́lì, nígbà tí o bá gbọ́ ọ̀rọ̀ ẹnu mi, kí o bá mi kìlọ̀ fún wọn.+

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́