17Nígbà náà, Èlíjà*+ ará Tíṣíbè, tó ń gbé ní Gílíádì+ sọ fún Áhábù pé: “Bí Jèhófà Ọlọ́run Ísírẹ́lì tí mò ń sìn* ti wà láàyè, kò ní sí òjò tàbí ìrì ní àwọn ọdún tó ń bọ̀, àfi nípa ọ̀rọ̀ mi!”+
14 Ló bá mú ẹ̀wù oyè Èlíjà tó já bọ́ lára rẹ̀, ó fi lu omi náà, ó sì sọ pé: “Jèhófà Ọlọ́run Èlíjà dà?” Nígbà tó lu omi náà, ó pín sí apá ọ̀tún àti sí apá òsì, tí Èlíṣà fi lè sọdá.+