ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • Jeremáyà 27:2, 3
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    • 2 “Ohun tí Jèhófà sọ fún mi nìyí, ‘Ṣe àwọn ọ̀já àti àwọn ọ̀pá àjàgà fún ara rẹ, kí o sì fi wọ́n sí ọrùn rẹ. 3 Lẹ́yìn náà, fi wọ́n ránṣẹ́ sí ọba Édómù,+ ọba Móábù,+ ọba àwọn ọmọ Ámónì,+ ọba Tírè+ àti ọba Sídónì+ nípasẹ̀ àwọn òjíṣẹ́ tó wá sí Jerúsálẹ́mù sọ́dọ̀ Sedekáyà ọba Júdà.

  • Jeremáyà 49:3
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    •  3 ‘Pohùn réré ẹkún, ìwọ Hẹ́ṣíbónì nítorí wọ́n ti pa Áì run!

      Ẹ figbe ta, ẹ̀yin àrọko Rábà.

      Wọ aṣọ ọ̀fọ̀.*

      Pohùn réré ẹkún, kí o sì lọ káàkiri láàárín àwọn ọgbà ẹran tí a fi òkúta ṣe,*

      Nítorí Málíkámù máa lọ sí ìgbèkùn,

      Pẹ̀lú àwọn àlùfáà rẹ̀ àti àwọn ọmọ aládé rẹ̀.+

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́