ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • Sáàmù 46:1
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    • 46 Ọlọ́run ni ibi ààbò wa àti okun wa,+

      Ìrànlọ́wọ́ tó wà lárọ̀ọ́wọ́tó ní àkókò wàhálà.+

  • Sáàmù 91:2
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    •  2 Màá sọ fún Jèhófà pé: “Ìwọ ni ibi ààbò mi àti odi ààbò mi,+

      Ọlọ́run mi tí mo gbẹ́kẹ̀ lé.”+

  • Òwe 18:10
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    • 10 Orúkọ Jèhófà jẹ́ ilé gogoro tó lágbára.+

      Olódodo sá wọ inú rẹ̀, ó sì rí ààbò.*+

  • Àìsáyà 25:4
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    •  4 Torí o ti di ibi ààbò fún ẹni rírẹlẹ̀,

      Ibi ààbò fún aláìní nínú ìdààmú rẹ̀,+

      Ibi ààbò kúrò lọ́wọ́ ìjì òjò,

      Àti ibòji kúrò lọ́wọ́ ooru.+

      Nígbà tí atẹ́gùn líle àwọn ìkà bá dà bí ìjì òjò tó kọ lu ògiri,

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́