22 Ohun tó mú kí àwọn òbí rẹ̀ sọ àwọn nǹkan yìí ni pé wọ́n ń bẹ̀rù àwọn Júù,+ torí àwọn Júù ti fohùn ṣọ̀kan tẹ́lẹ̀ pé, tí ẹnikẹ́ni bá gbà pé òun ni Kristi, wọ́n máa lé ẹni yẹn kúrò nínú sínágọ́gù.+
2 Àwọn èèyàn máa lé yín kúrò nínú sínágọ́gù.+ Kódà, wákàtí náà ń bọ̀, nígbà tí ẹnikẹ́ni tó bá pa yín+ máa rò pé ṣe lòun ń ṣe iṣẹ́ ìsìn mímọ́ fún Ọlọ́run.