22 Nígbà tí wọ́n débẹ̀, wọ́n fún àwọn ọmọ ẹ̀yìn* lókun,+ wọ́n fún wọn ní ìṣírí láti má ṣe kúrò nínú ìgbàgbọ́, wọ́n sì sọ pé: “A gbọ́dọ̀ ti inú ọ̀pọ̀ ìpọ́njú wọ Ìjọba Ọlọ́run.”+
9 Nítorí lójú tèmi, ó dà bíi pé Ọlọ́run ti fi àwa àpọ́sítélì sí ìgbẹ̀yìn láti fi wá hàn bí àwọn tí a ti dájọ́ ikú fún,+ nítorí a ti di ìran àpéwò fún ayé+ àti fún àwọn áńgẹ́lì àti fún àwọn èèyàn.