-
Jeremáyà 25:15Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
-
-
15 Nítorí ohun tí Jèhófà Ọlọ́run Ísírẹ́lì sọ fún mi nìyí: “Gba ife wáìnì ìbínú yìí ní ọwọ́ mi, kí o sì mú kí gbogbo orílẹ̀-èdè tí mo bá rán ọ sí mu ún.
-
-
Ìfihàn 14:9, 10Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
-
-
9 Áńgẹ́lì kẹta tẹ̀ lé wọn, ó sì ń fi ohùn tó dún ketekete sọ pé: “Tí ẹnikẹ́ni bá jọ́sìn ẹranko náà+ àti ère rẹ̀, tó sì gba àmì kan sí iwájú orí rẹ̀ tàbí sí ọwọ́ rẹ̀,+ 10 òun náà máa mu nínú wáìnì ìbínú Ọlọ́run tó tú jáde láìní àbùlà sínú ife ìbínú Rẹ̀,+ a sì máa fi iná àti imí ọjọ́+ dá a lóró níwájú àwọn áńgẹ́lì mímọ́ àti níwájú Ọ̀dọ́ Àgùntàn náà.
-