ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • Sáàmù 142
  • Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Sáàmù

      • Àdúrà ìdáǹdè kúrò lọ́wọ́ àwọn tó ń ṣe inúnibíni

        • “Kò síbi tí mo lè sá lọ” (4)

        • ‘Ìwọ ni gbogbo ohun tí mo ní’ (5)

Sáàmù 142:àkọlé

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Wo Àlàyé Ọ̀rọ̀.

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +1Sa 22:1; 24:3; Heb 11:32, 38

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    Ilé Ìṣọ́,

    9/15/2011, ojú ìwé 10

Sáàmù 142:1

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Sm 28:2; 141:1

Sáàmù 142:2

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Sm 18:6; Jon 2:7; Mt 26:38, 39; Mk 15:34; Heb 5:7

Sáàmù 142:3

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “tí mi ò lágbára mọ́.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Sm 139:3

Sáàmù 142:4

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Ní Héb., “tó dá mi mọ̀.”

  • *

    Tàbí “ọ̀rọ̀ ọkàn mi.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Sm 31:11; 69:20
  • +1Sa 23:11

Sáàmù 142:5

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Ní Héb., “Ìpín mi.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Owe 18:10

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    Ilé Ìṣọ́,

    9/15/2011, ojú ìwé 10-11

Sáàmù 142:6

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +1Sa 20:33; 23:26; 25:29

Sáàmù 142:7

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “ọkàn mi.”

Àwọn míì

Sm 142:àkọlé1Sa 22:1; 24:3; Heb 11:32, 38
Sm 142:1Sm 28:2; 141:1
Sm 142:2Sm 18:6; Jon 2:7; Mt 26:38, 39; Mk 15:34; Heb 5:7
Sm 142:3Sm 139:3
Sm 142:4Sm 31:11; 69:20
Sm 142:41Sa 23:11
Sm 142:5Owe 18:10
Sm 142:61Sa 20:33; 23:26; 25:29
  • Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
  • 1
  • 2
  • 3
  • 4
  • 5
  • 6
  • 7
Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
Sáàmù 142:1-7

Sáàmù

Másíkílì.* Ti Dáfídì, nígbà tó wà nínú ihò àpáta.+ Àdúrà.

142 Mo fi ohùn mi ké pe Jèhófà fún ìrànlọ́wọ́;+

Mo fi ohùn mi bẹ Jèhófà pé kó ṣojú rere sí mi.

2 Mo tú ẹ̀dùn ọkàn mi jáde níwájú rẹ̀;

Mo sọ nípa wàhálà mi níwájú rẹ̀+

3 Nígbà tí àárẹ̀ mú ẹ̀mí mi.*

Ò ń ṣọ́ ọ̀nà mi.+

Wọ́n dẹ pańpẹ́ pa mọ́ dè mí

Ní ọ̀nà tí mò ń rìn.

4 Wo ọwọ́ ọ̀tún mi, kí o sì rí i

Pé kò sẹ́ni tó rí tèmi rò.*+

Kò síbi tí mo lè sá lọ;+

Kò sẹ́ni tí ọ̀rọ̀ mi* ká lára.

5 Jèhófà, mo ké pè ọ́ fún ìrànlọ́wọ́.

Mo sọ pé: “Ìwọ ni ibi ààbò mi,+

Gbogbo ohun tí mo ní* lórí ilẹ̀ alààyè.”

6 Fetí sí igbe mi fún ìrànlọ́wọ́,

Nítorí wọ́n ti bá mi kanlẹ̀.

Gbà mí lọ́wọ́ àwọn tó ń ṣe inúnibíni sí mi,+

Torí wọ́n lágbára jù mí lọ.

7 Mú mi* jáde kúrò nínú àjà ilẹ̀

Kí n lè máa yin orúkọ rẹ.

Kí àwọn olódodo yí mi ká,

Nítorí o ti ṣemí lóore.

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́