ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • 1 Sámúẹ́lì 27
  • Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

Ohun Tó Wà Nínú Ìwé 1 Sámúẹ́lì

      • Àwọn Filísínì fún Dáfídì ní Síkílágì (1-12)

1 Sámúẹ́lì 27:1

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +1Sa 19:18; 22:1, 5
  • +1Sa 18:29; 23:23

1 Sámúẹ́lì 27:2

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +1Sa 25:13; 30:9
  • +1Sa 21:10, 14; 27:12

1 Sámúẹ́lì 27:3

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +1Sa 25:43
  • +1Sa 25:39, 42

1 Sámúẹ́lì 27:4

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +1Sa 23:14; 26:25

1 Sámúẹ́lì 27:6

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Joṣ 19:1, 5; 1Sa 30:1; 2Sa 1:1; 1Kr 12:1, 20

1 Sámúẹ́lì 27:7

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Ní Héb., “Iye ọjọ́.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +1Sa 29:3

1 Sámúẹ́lì 27:8

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Joṣ 13:1, 2
  • +Jẹ 36:12; Ẹk 17:8, 14; Nọ 13:29; 1Sa 15:2; 2Sa 1:1
  • +Jẹ 25:17, 18; Ẹk 15:22; 1Sa 15:7

1 Sámúẹ́lì 27:9

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Di 25:19; 1Sa 15:3

1 Sámúẹ́lì 27:10

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “Négébù.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Joṣ 15:1, 2
  • +1Kr 2:9
  • +Nọ 24:21; 1Sa 15:6

Àwọn míì

1 Sám. 27:11Sa 19:18; 22:1, 5
1 Sám. 27:11Sa 18:29; 23:23
1 Sám. 27:21Sa 25:13; 30:9
1 Sám. 27:21Sa 21:10, 14; 27:12
1 Sám. 27:31Sa 25:43
1 Sám. 27:31Sa 25:39, 42
1 Sám. 27:41Sa 23:14; 26:25
1 Sám. 27:6Joṣ 19:1, 5; 1Sa 30:1; 2Sa 1:1; 1Kr 12:1, 20
1 Sám. 27:71Sa 29:3
1 Sám. 27:8Joṣ 13:1, 2
1 Sám. 27:8Jẹ 36:12; Ẹk 17:8, 14; Nọ 13:29; 1Sa 15:2; 2Sa 1:1
1 Sám. 27:8Jẹ 25:17, 18; Ẹk 15:22; 1Sa 15:7
1 Sám. 27:9Di 25:19; 1Sa 15:3
1 Sám. 27:10Joṣ 15:1, 2
1 Sám. 27:101Kr 2:9
1 Sám. 27:10Nọ 24:21; 1Sa 15:6
  • Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
  • 1
  • 2
  • 3
  • 4
  • 5
  • 6
  • 7
  • 8
  • 9
  • 10
  • 11
  • 12
Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
1 Sámúẹ́lì 27:1-12

Sámúẹ́lì Kìíní

27 Àmọ́ Dáfídì sọ nínú ọkàn rẹ̀ pé: “Lọ́jọ́ kan, Sọ́ọ̀lù máa pa mí. Ohun tó máa dáa jù ni pé kí n sá lọ+ sí ilẹ̀ àwọn Filísínì; ìgbà yẹn ni Sọ́ọ̀lù á jáwọ́ nínú wíwá mi kiri ní gbogbo ìpínlẹ̀ Ísírẹ́lì,+ màá sì bọ́ lọ́wọ́ rẹ̀.” 2 Ni Dáfídì àti ọgọ́rùn-ún mẹ́fà (600) ọkùnrin+ tí ó wà pẹ̀lú rẹ̀ bá gbéra, wọ́n sì lọ sọ́dọ̀ Ákíṣì+ ọmọ Máókì, ọba Gátì. 3 Dáfídì dúró sọ́dọ̀ Ákíṣì ní Gátì, òun àti àwọn ọkùnrin rẹ̀, kálukú pẹ̀lú agbo ilé rẹ̀. Àwọn ìyàwó Dáfídì méjèèjì sì wà pẹ̀lú rẹ̀, Áhínóámù+ ará Jésírẹ́lì àti Ábígẹ́lì,+ opó Nábálì, ará Kámẹ́lì. 4 Nígbà tí wọ́n sọ fún Sọ́ọ̀lù pé Dáfídì ti sá lọ sí Gátì, kò tún wá a kiri mọ́.+

5 Nígbà náà, Dáfídì sọ fún Ákíṣì pé: “Tí mo bá rí ojú rere rẹ, jẹ́ kí wọ́n fún mi ní àyè nínú ọ̀kan lára àwọn ìlú tó wà ní ìgbèríko, kí n lè máa gbé ibẹ̀. Kí nìdí tí ìránṣẹ́ rẹ á fi máa bá ọ gbé nínú ìlú ọba?” 6 Torí náà, Ákíṣì fún un ní Síkílágì+ ní ọjọ́ yẹn. Ìdí nìyẹn tí Síkílágì fi jẹ́ ti àwọn ọba Júdà títí di òní yìí.

7 Àkókò* tí Dáfídì fi gbé ní ìgbèríko àwọn Filísínì jẹ́ ọdún kan àti oṣù mẹ́rin.+ 8 Dáfídì máa ń jáde lọ pẹ̀lú àwọn ọkùnrin rẹ̀ kí wọ́n lè kó nǹkan àwọn ará Géṣúrì+ àti àwọn Gísì àti àwọn ọmọ Ámálékì,+ nítorí wọ́n ń gbé ilẹ̀ tí ó lọ láti Télámù títí dé Ṣúrì+ àti títí dé ilẹ̀ Íjíbítì. 9 Nígbà tí Dáfídì bá lọ gbéjà ko ilẹ̀ náà, kì í dá ọkùnrin tàbí obìnrin sí,+ àmọ́ á kó àwọn agbo ẹran àti ọ̀wọ́ ẹran àti kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ àti ràkúnmí àti aṣọ, lẹ́yìn náà, á wá pa dà sọ́dọ̀ Ákíṣì. 10 Ákíṣì á béèrè lọ́wọ́ rẹ̀ pé: “Ibo ni ẹ ti lọ kó nǹkan lónìí?” Dáfídì á dáhùn pé: “Apá gúúsù* Júdà”+ tàbí “Apá gúúsù àwọn ọmọ Jéráméélì”+ tàbí “Apá gúúsù àwọn Kénì”+ ni. 11 Dáfídì kì í dá ọkùnrin tàbí obìnrin kankan sí tó máa mú wá sí Gátì, á sọ pé: “Kí wọ́n má bàa rojọ́ wa fún wọn pé, ‘Ohun tí Dáfídì ṣe nìyí.’” (Bí ó sì ṣe máa ń ṣe nìyẹn ní gbogbo ìgbà tó fi ń gbé ní ìgbèríko àwọn Filísínì.) 12 Nítorí náà, Ákíṣì gba Dáfídì gbọ́, ó sì ń sọ fún ara rẹ̀ pé: ‘Ó dájú pé ó ti di ẹni ìkórìíra láàárín àwọn èèyàn rẹ̀ Ísírẹ́lì, torí náà, á máa jẹ́ ìránṣẹ́ mi títí lọ.’

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́