ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • od ojú ìwé 213-222
  • Atọ́ka Àwọn Àkòrí

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Atọ́ka Àwọn Àkòrí
  • A Ṣètò Wa Láti Ṣe Ìfẹ́ Jèhófà
A Ṣètò Wa Láti Ṣe Ìfẹ́ Jèhófà
od ojú ìwé 213-222

Atọ́ka Àwọn Àkòrí

Àkíyèsí: Àwọn nọ́ńbà tó wà níwájú ọ̀rọ̀ kọ̀ọ̀kan ló sọ ibi tá a ti lè rí àlàyé nípa kókó ọ̀rọ̀ náà. Nọ́ńbà àkọ́kọ́ tọ́ka sí orí, èkejì sì tọ́ka sí ìpínrọ̀. Bí àpẹẹrẹ, “akéde: 10:​4-5” ni kókó àkọ́kọ́ lábẹ́ àkòrí náà, “Àfojúsùn.” Èyí túmọ̀ sí pé tẹ́ ẹ bá fẹ́ mọ ibi tá a ṣàlàyé nípa ohun tí akéde kan lè fi ṣe àfojúsùn rẹ̀, ẹ máa rí i ní Orí 10, ìpínrọ̀ 4 àti 5.

Àdúgbò tí wọ́n ti ń sọ èdè ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀: 9:​35-44

àwùjọ àtàwọn tí kò tíì di àwùjọ: 9:​42-44

kíkọ́ èdè: 10:10

tí onílé bá ń sọ èdè tó yàtọ̀: 9:​38-41

Àfojúsùn

akéde: 10:​4-5

àwọn ilé ẹ̀kọ́ ètò Ọlọ́run: 10:​17-18

ìdí tó fi ṣe pàtàkì: 10:​24-26

iṣẹ́ alábòójútó àyíká: 10:16

iṣẹ́ ìkọ́lé: 10:​21-23

iṣẹ́ ìsìn aṣáájú-ọ̀nà: 10:​11-14

iṣẹ́ ìsìn Bẹ́tẹ́lì: 10:​19-20

kíkọ́ èdè míì: 10:10

míṣọ́nnárì tó ń sìn ní pápá: 10:15

mọ ohun tó o lè ṣe: 8:37

sísìn níbi tí wọ́n ti nílò oníwàásù púpọ̀ sí i: 10:​6-9

Àìgbọ́ra-ẹni-yé

èyí tó lágbára: 14:​13-20

pẹ́ẹ́pẹ̀ẹ̀pẹ́: 14:​5-6

Akéde

(Wo Akéde ìjọ; Akéde tí kò tíì ṣèrìbọmi)

Akéde ìjọ

(Tún wo Akéde tí kò tíì ṣèrìbọmi)

ohun tó gbọ́dọ̀ kúnjú ìwọ̀n rẹ̀: 8:8

ọ̀dọ́: 8:​13-14

ríran akéde kọ̀ọ̀kan lọ́wọ́: 5:​28-29, 33; 7:21; 9:​7, 15, 19

tí ara wọn ò le: 8:29

tó kó lọ sí ìjọ míì: 8:30

tuntun: 8:​5-6

Akéde tí kò tíì ṣèrìbọmi

bó o ṣe lè kúnjú ìwọ̀n: 8:​6-12

ìwà àìtọ́: 14:​38-40

kíkọ́ tàbí títún Gbọ̀ngàn Ìjọba ṣe: 11:17

ọmọdé: 8:​13-15

Àkọsílẹ̀ Akéde Ìjọ: 5:44; 8:​10, 30

Akọ̀wé: 5:27; 8:30

Alábòójútó (àwọn)

(Wo Alàgbà)

Alábòójútó àyíká

àwùjọ: 9:44

dídámọ̀ràn ìjọ tuntun: 7:22

ìbẹ̀wò alábòójútó àyíká: 5:​41-48

ṣíṣe alábòójútó àyíká lálejò: 5:50

tó o bá fẹ́ mú iṣẹ́ òjíṣẹ́ rẹ gbòòrò sí i: 10:​6, 10, 16, 20

Alábòójútó iṣẹ́ ìsìn: 5:​28, 32; 9:​31, 37, 45

Alàgbà

àgbàlagbà tàbí ẹni tára rẹ̀ kò le: 5:​23-24

àwùjọ àtàwọn tó fẹ́ di àwùjọ: 9:​42-44

bó o ṣe lè kúnjú ìwọ̀n: 5:22

ìfọwọ́sowópọ̀ láàárín àwọn alàgbà: 5:21

ìpàdé àwọn alàgbà: 5:37

iṣẹ́ wọn: 5:​25-36, 40

ìwà wa sí àwọn alàgbà: 3:14; 5:​38-39

ìyànsípò wọn bá ìlànà Ọlọ́run mu: 4:8

mímú kí ìjọ wà ní mímọ́: 14:​19-40

ohun tí wọ́n kúnjú ìwọ̀n ká tó yàn wọ́n: 5:​4-20

olùṣọ́ àgùntàn: 5:​1-3; 14:​7-12

Àpéjọ agbègbè: 7:​25-27

Àpéjọ (àwọn)

(Wo Àpéjọ àyíká)

Àpéjọ àyíká

bá a ṣe ń ṣètò àpéjọ: 5:49

ibi tá a ti máa ń ṣe é: 11:18

ìnáwó: 12:​8-11

Arábìnrin (àwọn)

àwọn ilé ẹ̀kọ́ ètò Ọlọ́run: 10:​17-18

bí kò bá sí arákùnrin tó tóótun: 6:9; 7:23

iṣẹ́ ìkọ́lé: 10:21

Aṣáájú-ọ̀nà: 10:​11-14

Aṣáájú-ọ̀nà àkànṣe: 10:​11, 14, 17-18

Aṣáájú-ọ̀nà olùrànlọ́wọ́: 10:​11-12

Aṣọ wíwọ̀ àti ìmúra

àwọn tó lẹ́rù iṣẹ́: 6:9

ìránṣẹ́ iṣẹ́ òjíṣẹ́: 6:5

iṣẹ́ ìwàásù: 13:12

nígbà ìgbafẹ́: 13:14

nípàdé: 11:​12, 21

tá a bá lọ sí Bẹ́tẹ́lì: 13:13

Aṣojú orílé-iṣẹ́: 5:​55-56

Àsọyé fún gbogbo èèyàn: 7:​5-10

Àwòfiṣàpẹẹrẹ

ohun tó túmọ̀ sí: 6:9

Àwọn àjọ tá à ń lò: 4:12

Àwọn aláìní: 12:​12-15

Àwọn ọmọ

bí àwọn ọ̀dọ́kùnrin ṣe lè kúnjú ìwọ̀n láti di ìránṣẹ́: 6:14

ìpàdé ìjọ (àwọn): 7:2; 11:​13-14

iléèwé: 13:​22-24

ìtẹ̀síwájú nípa tẹ̀mí: 8:​13-15; 10:26; ojú ìwé 179-181

ṣíṣèrànwọ́ fún àwọn òbí àtàwọn òbí àgbà tí ara wọn ò le: 12:14

tí wọ́n bá hùwà àìtọ́: 14:37

Àwùjọ tí akéde kọ̀ọ̀kan wà

alábòójútó: 5:​29-34

ìpàdé iṣẹ́ ìsìn pápá: 7:​20-21

ìpínlẹ̀ ìwàásù: 9:​31, 33

ojúṣe ìránṣẹ́ iṣẹ́ òjíṣẹ́: 6:12

ṣíṣe ìmọ́tótó Gbọ̀ngàn Ìjọba: 11:7

yíyan àwọn akéde sí àwùjọ: 5:35

Dídi òjíṣẹ́: 8:3

Eré ìtura àti eré ìnàjú: 13:​15-21

Ètò Ìsìnkú: 11:​10-11

Ètò Jèhófà

apá ti òkè ọ̀run: 1:​8-13

Ẹ̀ka ọ́fíìsì

ìmúra àti aṣọ wa tá a bá ń lọ sí ẹ̀ka ọ́fíìsì: 13:13

ojúṣe àwọn tó ń bójú tó ẹ̀ka ọ́fíìsì: 4:13

ọrẹ tá à ń fi ránṣẹ́: 12:​2-4

tá ò bá lè kàn sí ẹ̀ka ọ́fíìsì: 17:​15-17

“Ẹrú olóòótọ́ àti olóye”

bá a ṣe ń fi hàn pé a fọkàn tán ẹrú náà: 3:​12-15

bá a ṣe lè mọ ẹrú náà: 3:​4-6

fífi ara wa sábẹ́ rẹ̀: 15:7

Fífi owó ṣètìlẹyìn

àyíká: 12:​8-11

ìjọ: 11:​6-7; 12:​5-7

kárí ayé: 11:15; 12:​2-4

Gbígba ẹni tá a yọ lẹ́gbẹ́ pa dà; Ìgbàpadà: 14:​34-36

Gbọ̀ngàn Àpéjọ: 11:​18-21

Gbọ̀ngàn Ìjọba

ibi ìkówèésí: 7:19

ìjọ tó ju ẹyọ kan lọ: 11:​8-9

ìmọ́tótó àti àtúnṣe: 11:​7-8

ìnáwó: 11:6; 12:​5-6

ìyàsímímọ́: 11:4

kíkọ́ gbọ̀ngàn ìjọba: 10:​21-23; 11:​4-5, 15-17

lílò fún àwọn ohun àkànṣe: 11:​10-11

Ìbáwí: 14:​4, 23-24

Ìdẹwò, àdánwò: 13:​4-5; 17:​4-19

Ìfilọ̀

akéde tí kò tíì ṣèrìbọmi: 8:12; 14:​39-40

ìbáwí: 14:24

ìgbàpadà: 14:36

ìyọlẹ́gbẹ́: 14:29

mímú ara ẹni kúrò lẹ́gbẹ́: 14:33

ọrẹ: 12:6

Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni​—Ìwé Ìpàdé: 7:​14-18

Ìgbéyàwó: 11:​10-11

Ìgbìmọ̀

Alárinà Ilé Ìwòsàn: 5:40

Ẹ̀ka: 4:13; 5:​51-54

Ìgbìmọ̀ Iṣẹ́ Ìsìn Ìjọ: 5:35

ìgbẹ́jọ́: 14:​21-28, 34-37

Orílẹ̀-èdè: 5:53

Tó Ń Bójú Tó Gbọ̀ngàn Ìjọba: 11:8

Ìgbìmọ̀ Alárinà Ilé Ìwòsàn àti Àwùjọ Tó Ń Bẹ Àwọn Aláìsàn Wò: 5:40

Ìgbìmọ̀ iṣẹ́ ìsìn

(Wo Ìgbìmọ̀ Iṣẹ́ Ìsìn Ìjọ)

Ìgbìmọ̀ Iṣẹ́ Ìsìn Ìjọ: 5:35

Ìgbìmọ̀ Olùdarí

bá a ṣe lè fi hàn pé a fọkàn tán an: 3:​12-15

bá a ṣe lè mọ ìgbìmọ̀ olùdarí: 3:​1-6

ìdí tó fi yẹ ká máa tẹ̀ lé ìtọ́ni ìgbìmọ̀ náà: 3:​9-11; 4:​9-11

Ìgbìmọ̀ ìgbẹ́jọ́: 14:​21-28, 34-37

Ìjọ

(Tún wo Gbọ̀ngàn Ìjọba; Ìpàdé)

a ṣètò wọn lọ́nà ti Ọlọ́run: 1:3; 4:​4-11

ìṣọ̀kan: 13:​28-30

tuntun àti kékeré: 7:​22-23

Ìkẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì

dídarí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ sínú ètò Ọlọ́run: 9:​20-21

ìdí tí ìkẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì fi ṣe pàtàkì: 9:​16-17

ríròyìn ìkẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì: 8:26

rírọ akẹ́kọ̀ọ́ láti máa wàásù lọ́nà àìjẹ́-bí-àṣà: 8:5

Ìkẹ́kọ̀ọ́ Ilé Ìṣọ́: 7:​11-13

Ìmọ́tótó

Gbọ̀ngàn Ìjọba: 11:​7-8

nínú ìwà, nínú ìjọsìn: 13:​6-7

nípa tara: 13:​8-12

Ìpàdé

alàgbà (àwọn): 5:37

àpéjọ agbègbè: 7:​25-26

àpéjọ àyíká: 7:24

àsọyé fún gbogbo èèyàn: 7:​5-10

àwọn ọmọ Ísírẹ́lì: 11:1

àwọn ọmọdé tó wá: 11:13

bí ìjọba bá fòfin de: 17:​15-17

bó ṣe ṣe pàtàkì: 3:12; 7:​4, 27; 15:7

ibi ìpàdé: 11:​1-5, 18-19

ìdí tá a fi ń ṣe é: 7:​1-2

Ìkẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì Ìjọ: 7:17

Ìkẹ́kọ̀ọ́ Ilé Ìṣọ́: 7:​11-13

Ìpàdé Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́: 7:​14-19

ìpolówó ọjà níbẹ̀: 13:27

iṣẹ́ ìsìn pápá: 7:​20-21; 9:45

nígbà ìbẹ̀wò alábòójútó àyíká: 5:​43, 47

olùtọ́jú èrò: 11:14

ọgọ́rùn-ún ọdún kìíní: 7:3; 11:2

tí arábìnrin bá darí: 7:23

Ìpínlẹ̀ ìwàásù

àkọsílẹ̀: 9:31

àwùjọ àti ti ara ẹni: 9:​31-34

èdè ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀: 9:​36-37

Ìpinnu ìjọ: 12:​6, 9, 11

Ipò iwájú

àwọn aláṣẹ ìlú: 15:11

nínú ètò Jèhófà: 1:​9-10; 2:​5, 9-10; 15:​1-2

nínú ìdílé: 15:​9-10

nínú ìjọ: 3:14; 4:15; 15:7

Ìránṣẹ́ iṣẹ́ òjíṣẹ́

bó o ṣe lè di: 6:14

fi ìmọrírì hàn fún: 6:​1-2, 15

ìtóótun: 6:​3-6

ojúṣe: 6:​7-12; 11:14

Ìrántí Ikú Kristi: 7:​28-30

Ìrànwọ́ nígbà àjálù: 12:15; 16:11

Ìrìbọmi

akéde tí kò tíì ṣèrìbọmi: ojú ìwé 182-184

dídi òjíṣẹ́: 8:3

ìbéèrè tá a máa ń bí àwọn tó fẹ́ ṣèrìbọmi: ojú ìwé 185-207

ìtumọ̀ ìrìbọmi: 8:​16-18

láwọn àpéjọ àyíká àti ti agbègbè: 7:​24, 26

ọmọdé: ojú ìwé 179-181

Ìròyìn

akéde: 5:34; 8:​10, 23-29

alábòójútó àyíká: 5:​46, 50; 9:44

bá ò bá sí nílé: 8:30

ìdí tó fi ṣe pàtàkì: 8:​19-22, 31-36

Iṣẹ́ ìkọ́lé: 10:​21-23

Ẹgbẹ́ Tó Ń Kọ́lé: 10:23

ìránṣẹ́ ìkọ́lé: 10:23

ìránṣẹ́ ìkọ́lé nílẹ̀ òkèèrè: 10:23

olùyọ̀ǹda lẹ́nu iṣẹ́ ìkọ́lé: 10:23

olùyọ̀ǹda tó ń yàwòrán ilé tó sì ń kọ́ ọ: 10:23

Iṣẹ́ ilé ìwé: 13:​22-24

Iṣẹ́ ìsìn Bẹ́tẹ́lì: 10:​19-20

Iṣẹ́ oúnjẹ òòjọ́: 13:​25-26

Ìṣọ̀kan

alàgbà: 5:​13, 21

ìbùkún: 4:15; 5:57; 13:​30-31

ìṣòro: 14:3; 17:6

kárí ayé: 16:​6-11

lábẹ́ ìdarí Kristi: 2:​9-11; 4:​10-11

ohun tó jẹ́ ká wà níṣọ̀kan: 1:​6-7; 13:​28-29

wíwà níṣọ̀kan nígbà gbogbo: 17:20

Ìtẹríba

(Wo Ipò iwájú)

Ìwà àìtọ́

(Wo Mímú ara ẹni kúrò lẹ́gbẹ́; Ìyọlẹ́gbẹ́; Sísàmì sí àwọn tó ń rìn ségesège; Àìgbọ́ra-ẹni-yé; Ìgbàpadà)

akéde tí kò tíì ṣèrìbọmi: 14:​38-40

bá a bá ṣẹ Kristẹni ẹlẹgbẹ́ wa: 14:​5-6, 13-20

èyí tó burú jáì: 14:​21-33

ìfilọ̀ nípa: 14:​24, 29, 33, 39-40

ọmọdé: 14:37

Ìwé

àdúgbò tí wọ́n ti ń sọ èdè ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀: 9:​36, 38

bá a ṣe ń lò ó fún ìwàásù: 9:​22-23

bá a ṣe ń rówó tẹ̀ ẹ́: 12:​2-4

bá a ṣe ń gba ìwé: 12:16

Ìyàsímímọ́ àti ìrìbọmi

(Wo Ìrìbọmi)

Ìyọlẹ́gbẹ́: 14:​25-29

Jèhófà Ọlọ́run

bó o ṣe lè sún mọ́ ọn: 17:​1-3

Ọba Aláṣẹ Ayé Àtọ̀run: 15:​1-4

Jésù Kristi

Àlùfáà Àgbà: 2:4

Òjíṣẹ́: 8:​1-2; 9:1

Olùràpadà: 2:3

Olùṣọ́ Àgùntàn Àtàtà: 2:6; 5:1

Orí ìjọ: 1:10; 2:5

wà lábẹ́ Jèhófà: 15:5

JW.ORG: 9:​24-25

Kristẹni aláìṣiṣẹ́mọ́: 8:26; 14:32

Lílọ síbi tí wọ́n ti nílò oníwàásù púpọ̀ sí i: 10:​6-9

Mímú ara ẹni kúrò lẹ́gbẹ́: 14:​30-33

Míṣọ́nnárì: 10:​15, 18

Olùṣekòkáárí ìgbìmọ̀ àwọn alàgbà

akéde tuntun: 8:​8, 14

àwọn tó fẹ́ ṣèrìbọmi: 8:18; ojú ìwé 208-212

ìbẹ̀wò alábòójútó àyíká: 5:​42-44

Ìpàdé Ìgbésí Ayé àti Ìṣẹ́ Òjíṣẹ́: 7:18

ojúṣe rẹ̀: 5:26

yíyẹ àkáǹtì wò: 12:7

Olùtọ́jú èrò: 11:14

Ọrẹ: 3:13; 11:​6-7, 15; 12:​2-11

Oúnjẹ Alẹ́ Olúwa: 7:​28-30

Sísàmì sí àwọn tó ń rìn ségesège: 14:​9-12

Wíwàásù ìhìn rere

àdúgbò tí wọ́n ti ń sọ èdè ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀: 9:​35-44

àṣẹ Ọlọ́run: 8:2

àwọn ọ̀dọ́: 8:​13-15

bó o ṣe lè kúnjú ìwọ̀n: 8:​6-9, 13-15

ìdí tó fi ṣe pàtàkì: 9:​5-8; 10:​1-2

ìjẹ́rìí àjẹ́pọ̀: 9:​45-46

ilé-dé-ilé: 9:​3-9

ìmúra: 13:12

ìpadàbẹ̀wò: 9:​14-15

ìpàdé iṣẹ́ ìsìn pápá: 7:​20-21

ìpínlẹ̀ ìwàásù: 9:​30-34

ìrànlọ́wọ́ látọ̀dọ̀ àwọn míì: 5:​28-29, 33; 7:21; 9:​7, 15, 19

ìròyìn: 8:​19-29, 31-36

iṣẹ́ alábòójútó iṣẹ́ ìsìn: 5:28

ìwé: 9:​22-23

lábẹ́ ìfòfindè: 17:​13-18

láìjẹ́ bí àṣà: 9:​26-29

lílo ìkànnì jw.org: 9:​24-25

mímú ipò iwájú: 5:​3, 17, 29-33; 6:4

níbi tí èrò pọ̀ sí: 9:​11-12

ọgọ́rùn-ún ọdún kìíní: 8:​1-2; 9:​1, 4

sọ fún akẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì pé kó máa wàásù láìjẹ́ bí àṣà: 8:5

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́