ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • w93 12/15 ojú ìwé 31
  • Atọ́ka Àwọn Kókó-ẹ̀kọ́ Fún Ilé-ìṣọ́nà 1993

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Atọ́ka Àwọn Kókó-ẹ̀kọ́ Fún Ilé-ìṣọ́nà 1993
  • Ilé-Ìṣọ́nà Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—1993
  • Ìsọ̀rí
  • ÀWỌN ẸLẸ́RÌÍ JEHOFA
  • ÀWỌN ÌTÀN ÌGBÉSÍ-AYÉ
  • ÀWỌN OLÙPÒKÌKÍ ÌJỌBA RÒYÌN
  • BIBELI
  • ÌBÉÈRÈ LÁTI ỌWỌ́ ÀWỌN ÒǸKÀWÉ
  • ÌGBÉSÍ-AYÉ ÀTI ÀWỌN ÀNÍMỌ́ KRISTIAN
  • ÌRÍSÍ ÌRAN LÁTI ILẸ̀ ÌLÉRÍ
  • JEHOFA
  • JESU KRISTI
  • LÁJORÍ ÀWỌN Ọ̀RỌ̀ ÌKẸ́KỌ̀Ọ́
  • Ọ̀KANKÒJỌ̀KAN
Ilé-Ìṣọ́nà Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—1993
w93 12/15 ojú ìwé 31

Atọ́ka Àwọn Kókó-ẹ̀kọ́ Fún Ilé-ìṣọ́nà 1993

Tí ń tọ́ka ọjọ́ ìtẹ̀jáde nínú èyí tí ọ̀rọ̀-ẹ̀kọ́ fárahàn

ÀWỌN ẸLẸ́RÌÍ JEHOFA

Àwọn Àpéjọpọ̀ Àgbègbè “Àwọn Olùtan Ìmọ́lẹ̀” 1/15

Àwọn Àpéjọpọ̀ Àgbègbè “Ẹ̀kọ́ Àtọ̀runwá,” 6/1

Àwọn Ìpèsè Ìrànlọ́wọ́ Fi Ìfẹ́ Kristian Hàn (Russia, Ukraine), 2/1

Àwọn Òjíhìn-Iṣẹ́-Ọlọ́run ní Micronesia, 3/1

“Àwọn Olùpòkìkí Ìjọba” Rìn Lórí Ọ̀pọ̀lọpọ̀ Omi Guyana, 4/1

Fífi Ìfaradà Wàásù ní Ilẹ̀ Yìnyín àti Iná (Iceland), 9/15

Ìkẹ́kọ̀ọ́yege Gileadi, 12/1

Ilé-Ẹjọ́ Gíga ti Europe Gbèjà Ẹ̀tọ́ Láti Wàásù ni Greece, 9/1

Ilé-ẹ̀kọ́ Gilead Pé 50 Ọdún Ó Sì Ń Ṣaṣeyọrí! 6/1

Irú Àwárí Yíyàtọ̀ kan (Bahamas), 3/15

Jehofa Ń Dáàbòbo Àwọn Ènìyàn Rẹ̀ ní Hungary, 7/15

Jehofa Yí Àkókò àti Ìgbà Padà ní Romania, 6/15

Máa Báa Lọ Nínú Iṣẹ́-Ìsìn Aṣáájú-Ọ̀nà, 9/15

Ó Jà fún Ìgbàgbọ́ Rẹ̀ (C. Bazán Listán), 6/15

Ọlọrun Kò Gbàgbé “Ìfẹ́ tí Ẹ̀yin Fihàn” (Ìlà-Oòrùn Europe), 1/1

Rírí Ọrọ̀ Tòótọ́ ní Hong Kong, 5/15

Wíwàásù Láti Abúlé dé Abúlé ní Spain, 11/15

Wíwàásù ní Ilẹ̀ Onírúurú Ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ (Australia), 10/15

ÀWỌN ÌTÀN ÌGBÉSÍ-AYÉ

A Fi “Adé Ìyè” San Èrè fun Un (F. Franz), 3/15

Didagbasoke Pẹlu Eto-Ajọ Jehofa ni South Africa (F. Muller), 4/1

“Emi Niyi; Rán Mi” (W. John), 5/1

Jehofa, Igbẹkẹle Mi Lati Ìgbà Èwe Wá (B. Tsatos), 8/1

Jehofa Pa Iwalaaye Mi Mọ́ Ninu Ọgbà-Ẹ̀wọ̀n Aṣálẹ̀ Kan (I. Mnwe), 3/1

Mo Kún fún Ìmoore fún Itilẹyin Jehofa Tí Kìí Kùnà (S. Gaskins), 6/1

Mo Rí Itẹlọrun Ninu Ṣiṣiṣẹsin Ọlọrun (J. Thongoana), 2/1

Ogún-Ìní Ṣíṣọ̀wọ́n ti Kristian Kan (B. Brandt), 10/1

Ṣíṣiṣẹ́sìn Pẹ̀lú Òye Ìmọ̀lára Ìjẹ́kánjúkánjú (H. van Vuure), 11/1

Títẹ Iwe-Ikẹkọọ Bibeli Nigba Ti A Wà Labẹ Ifofinde (M. Vale), 7/1

ÀWỌN OLÙPÒKÌKÍ ÌJỌBA RÒYÌN

2/1, 3/1, 5/1, 7/1, 8/1, 10/1, 11/1

BIBELI

A Ha Nílò Bibeli Bí? 5/1

Atọ́nà Gbígbéṣẹ́ fún Ènìyàn Òde-Òní, 5/1

Àwọn Ìsọtẹ́lẹ̀ Bibeli, 5/15

Ẹ̀kọ́ Bibeli Nípa Ìrísí Ojú-Ilẹ̀, 6/15

Ọ̀rọ̀-Ìtàn Bibeli, 6/1

ÌBÉÈRÈ LÁTI ỌWỌ́ ÀWỌN ÒǸKÀWÉ

Àwọn aláìgbàgbọ́ tí ó kú ṣáájú ìpọ́njú ńlá, 5/15

Àwọn Kristian àti ìbàyíkájẹ́, 1/1

Bí a kò bá rí olùbáṣègbéyàwó, 1/15

Fífi owó kọ́ iyàn, 6/15

“Johannu Baptisi” tàbí “Johannu Arinibọmi”? 8/1

Kò lè wá síbi Ìṣe-ìrántí, 2/1

Melkisedeki ha wà “láìní ìlà ìdílé” bí? (Heb 7:3), 11/15

“Ní ẹ̀bùn ẹ̀mí” (1Kor 14:37), 10/15

O ha níláti da òwò pọ̀ pẹ̀lú aláìgbàgbọ́ kan bí? 10/1

Paulu ha fi ìwàláàyè rẹ̀ lélẹ̀ fún àwọn Ju bí? (Ro 9:3), 9/15

ÌGBÉSÍ-AYÉ ÀTI ÀWỌN ÀNÍMỌ́ KRISTIAN

Àwọn Kristian Ha Ń Pa Ọjọ́ Ìsinmi Mọ́ Bi? 2/15

Bí A Ṣe Lè Mú Ìdè Ìgbéyàwó Lókun Síi, 8/15

Bí Àwọn Kristian Ṣe Lè Ran Àwọn Àgbàlagbà Lọ́wọ́, 8/15

Bíbójútó Àwọn Arúgbó, 2/15

Èéṣe Tí O fi Níláti Gba Àṣìṣe? 11/15

Èéṣe Tí O Fí Níláti Lọ sí Àwọn Ìpàdé Kristian? 8/15

Èéṣe Tí O Fi Níláti Ṣiṣẹ́sin Jehofa? 5/15

Ẹ Jẹ́ Aláyọ̀ Kí Ẹ Sì Wà Létòlétò, 4/1

‘Ẹ Wá Jehofa, Gbogbo Ẹ̀yin Onínútútù,’ 12/15

Fífi Jẹ̀lẹ́ńkẹ́ Bójútó Àwọn Àgùtàn Ṣíṣeyebíye ti Jehofa, 7/15

Ìfẹ́ Aládùúgbò, 9/15

Ìjùmọ̀sọ̀rọ̀pọ̀—Ju Kìkì Ọ̀rọ̀ Sísọ Lásán Lọ, 8/1

Ìlànà Tàbí Ìgbajúmọ̀—Èwo ni? 10/1

Ìrètí—Ìdáàbòbò Ṣíṣekókó, 4/15

Ìwọ Ha Bọ̀wọ̀ fún Ibi Ìjọ́sìn Rẹ Bí? 6/15

Ìwọ Ha Ń Ṣe Gbogbo Ohun Tí O Lè Ṣe Bí? 4/15

Ìwọ Ha Ń Tọ Jehofa Lẹ́yìn Lẹ́kùn-ún-rẹ́rẹ́ Bí? 5/15

Jehofa Ń Rántí Àwọn Aláìsàn, Àwọn Àgbàlagbà, 8/1

Jíjẹ́ kí Ojú “Mú Ọ̀nà Kan” Nínú Iṣẹ́ Ìjọba, 12/15

Kíkẹ́kọ̀ọ́ Láti Dúró, 10/15

Kọ́kọ́rọ́ sí Ìgbésí-Ayé Ìdílé Aláṣeyọrísírere, 10/1

Ní Ojú-Ìwòye Títọ̀nà Nípa Àánú Ọlọrun, 10/1

Ògo-Ẹwà Orí-Ewú, 3/15

Olùfúnni ní “Gbogbo Ẹ̀bùn Rere,” 12/1

Ọlọrun Ń Mú Kí Ó Dàgbà—Ìwọ Ha Ń Kó Ipa Tìrẹ Bí? 3/1

Wọ́n Ń Fi Ìyọ́nú Ṣolùṣọ́ Àwọn Àgùtàn Kékeré Náà, 9/15

ÌRÍSÍ ÌRAN LÁTI ILẸ̀ ÌLÉRÍ

Beerṣeba, 7/1

Ẹ Yọ̀! Àwọn Ẹkù náà Kún fun Òróró ni Àkúnwọ́sílẹ̀, 3/1

Gerisimu, 1/1

Gileadi, 9/1

Òkun Galili, 11/1

Sinai—Oke Mose ati Àánú, 5/1

JEHOFA

Atóbilọ́lá Ẹlẹ́dàá Wa àti Àwọn Iṣẹ́ Rẹ̀, 1/1

Àwọn Ìṣe Ìgbàlà Jehofa Nísinsìnyí, 12/1

Àwọn Kristian Ìjímìjí Ha Lo Orúkọ Ọlọrun Bí? 11/1

Jehofa—Ọlọrun Òtítọ́ àti Alààyè, 7/15

Mímú Àdììtú Orúkọ Títóbilọ́lá Jùlọ náà Ṣe Kedere, 11/1

Olùfúnni ní ‘Gbogbo Ẹ̀bùn Rere,’ 12/1

Orúkọ Ọlọrun, 12/1

Ta Ni Jehofa? 7/15

JESU KRISTI

A Ha Bí I Ní Ìgbà Òjò-Dídì Bí? 12/15

LÁJORÍ ÀWỌN Ọ̀RỌ̀ ÌKẸ́KỌ̀Ọ́

Àánú Jehofa Ń Gbà Wá Là Kuro Ninu Ainireti, 3/15

Aláyọ̀ ni Àwọn Onírẹ̀lẹ̀-Ọkàn, 12/1

Àwọn Àpẹẹrẹ Ìrẹ̀lẹ̀-Ọkàn Láti Ṣàfarawé, 12/1

Àwọn Ìdílé Kristian Máa Ń Ṣe Nǹkan Papọ̀, 9/1

Àwọn Ìdílé Kristian Ń Fi Àwọn Ohun Tẹ̀mí Sí Ipò Àkọ́kọ́, 9/1

Àwọn Ìdílé Kristian Ń Ran Àwọn Àgbàlagbà Lọ́wọ́, 9/1

Awọn Igbokegbodo Ti A Mú Gbooro Sii Nigba Wíwàníhìn-ín Kristi, 5/1

Awọn Kristian ati Ẹgbẹ́ Awujọ Eniyan Lonii, 7/1

Àwọn Olùtan Ìmọ́lẹ̀—Fun Ète Wo? 1/15

Àwọn Ọjọ́ Alásọtẹ́lẹ̀ Danieli àti Ìgbàgbọ́ Wa, 11/1

Àwọn Wo Ni Wọn Ń Tẹle Ìmọ́lẹ̀ Ayé? 4/1

Bawo Ni A Ṣe Lè Fi Iwafunfun Kún Igbagbọ Wa? 7/15

Dahunpada si Awọn Ileri Ọlọrun Nipa Lilo Igbagbọ, 7/15

Eeṣe Ti A Fi Nilati Ṣọra fun Ibọriṣa? 1/15

Ẹ Fi Ìfọkànsìn Oníwà-bí-Ọlọ́run kún Ìfaradà Yín, 9/15

Ẹ Fi Imuratan Bojuto Agbo Ọlọrun, 5/15

Ẹ Gbẹ́kẹ̀lé Jehofa! 12/15

Ẹ Jẹ́ Ẹni Ti A Yipada Ni Ero-Inu Ti A Sì Làlóye Ni Ọkan-Aya, 3/1

Ẹ Jẹ́ Ki Ikora-Ẹni-Nijaanu Yin Wà Ki Ó Sì Kún Àkúnwọ́sílẹ̀, 8/15

Ẹ Maa Baa Lọ ni Didagba Ninu Ìmọ̀, 8/15

“Ẹ Maa Baa Lọ Ní Rírìn Gẹgẹ Bi Àwọn Ọmọ Ìmọ́lẹ̀,” 3/1

Ẹ Ní Ìgboyà Dáradára! 11/15

Ẹ Ṣọra fun Àwọn Orin Ti Kò Sunwọn! 4/15

Ẹ Ṣọra fun Gbogbo Oniruuru Ibọriṣa, 1/15

Ẹ Tẹle Ìmọ́lẹ̀ Ayé Naa, 4/1

Ẹ Yèkooro Ní Ero-Inu—Opin Ti Sunmọle, 6/1

Ẹyin Èwe—Kí Ni Ẹyin Ń Lépa? 4/15

Fifi Ẹmi Ifara-Ẹni-Rubọ Ṣiṣẹsin Jehofa, 6/1

Fi Tìgboyà-Tìgboyà Rìn Ní Àwọn Ọ̀nà Jehofa, 11/15

Idande Lakooko Ifarahan Jesu Kristi, 5/1

Ìfaradà—Ṣekókó fún Àwọn Kristian, 9/15

Ìfẹ́ (Agape)—Ohun Tí Kò Jẹ́ àti Ohun tí Ó Jẹ́, 10/15

Ìjagunmólú Ìkẹyìn ti Mikaeli, Balógun Ńlá Náà, 11/1

Iṣẹda Sọ Pe, ‘Wọn Wà Ní Àìríwí,’ 6/15

Itẹriba Oniwa-bi-Ọlọrun—Eeṣe ati Lati Ọwọ́ Ta Ni? 2/1

Jehofa Kò Gan Ọkàn Ìròbìnújẹ́, 3/15

‘Késí Àwọn Àgbà Ọkunrin,’ 5/15

“Ki Igbeyawo Ki O Ní Ọlá Laaarin Gbogbo Eniyan,” 2/15

Maṣe Jẹ́ Ki Ẹnikẹni Ba Ìwà Rere Rẹ Jẹ́, 8/1

Mímú Animọ-Iwa Titun Dagba Ninu Igbeyawo, 2/15

Mímú Ìbẹ̀rù Oníwà-bí-Ọlọ́run Dàgbà, 12/15

Mọ Jehofa Nípasẹ̀ Ọ̀rọ̀ Rẹ̀, 6/15

Ohun ti Itẹriba Oniwa-bi-Ọlọrun Ń Beere Lọwọ Wa, 2/1

Ọba kan Sọ Ibùjọsìn Jehofa Di Aláìmọ́, 11/1

Ọlọrun Ha Mọ̀ Ọ́ Níti Gidi Bí? 10/1

“Ọlọrun, Wádìí Mi,” 10/1

Rírìn Pẹlu Ọgbọ́n Sipa Ti Ayé, 7/1

Ṣaṣeyọri Ninu Yiyẹra fun Ìdẹkùn Ìwọra, 8/1

Ṣíṣàwárí Kọ́kọ́rọ́ Náà sí Ìfẹ́ni Ará, 10/15

Ṣíṣe Oluṣọ-agutan Pẹlu Atobilọla Ẹlẹdaa Wa, 1/1

Títan Ìmọ́lẹ̀ Sori Wíwàníhìn-ín Kristi, 5/1

Yíyọ̀ Ninu Atobilọla Ẹlẹdaa Wa, 1/1

Ọ̀KANKÒJỌ̀KAN

A Ha Pọ́n Ìfàjẹ̀sínilára Ju Bi Ó ti Yẹ Lọ Bí? 10/15

A Ó Ha Gbà Ọ́ Lọ Soke Ọrun Bi? 1/15

A Ṣẹ́gun “Ọ̀tá Ìkẹyìn”! 11/15

Aásìkí Lè Dán Igbagbọ Rẹ Wò, 7/15

Àwọn Aworan Isin, 4/15

Àwọn Ìjábá ti Ẹ̀dá, 12/1

Awọn Iṣẹda Titun Ni A Mú Jade! 1/1

Àwọn Kristian Ijimiji ati Ayé, 7/1

Àwọn Oògùn Oríire, 9/1

Báwo ni Ìwọ Ṣe Lè Wàláàyè Pẹ́ Tó? 11/15

Bí Kristẹndọm Ṣe Di Apakan Ayé Yii, 7/1

Ìfẹ Owó, 2/15

Ìjáfara Léwu! 3/1

Ìmukúmu-Ọtí, 8/15

Ìpalẹ̀-Ìdọ̀tí-Mọ́ Kari-Aye, 2/15

Ìpín Aláròyé Kìí Ṣe Ọ̀kan Ti Ó Jẹ́ Alayọ, 3/15

Ire Yoo Ha Bori Ibi Lae Bi? 2/1

Iwọ Ha Nilati Gba Iribọmi Bi? 4/1

Ki Ni Ó Beere fun Lati Mú Ọ Layọ? 6/1

Kò Sí Èrò Nípa Jijuwọ́sílẹ̀! (Àwọn Kristian Ìjímìjí), 11/15

Mẹ́talọ́kan—A Ha Fi Kọ́ni Nínú Bibeli Bí? 10/15

Olè Jíjà Yóò Ha Dópin Láé Bí? 10/15

Oúnjẹ Alẹ́ Oluwa, 3/15

Ọpa-Alade Pomegranate, 4/15

Ọrun-Apaadi, 4/15

Papias Ka Àwọn Ọ̀rọ̀ Oluwa sí Iyebíye, 9/15

Rahabu—A Polongo Rẹ̀ Ní Olódodo Nípa Àwọn Iṣẹ́ Ìgbàgbọ́, 12/15

Ṣe Iribọmi! Ṣe Iribọmi! Ṣe Iribọmi!—Ṣugbọn Eeṣe? 4/1

Ṣọọṣi Latin-America Ninu Idaamu, 6/15

Tábà ati Awujọ-alufaa, 2/1

Yẹra fun Ẹmi Ìgbéraga! 5/15

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́