ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • w00 12/15 ojú ìwé 31
  • Atọ́ka Kókó Àpilẹ̀kọ Fún Ilé Ìṣọ́ 2000

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Atọ́ka Kókó Àpilẹ̀kọ Fún Ilé Ìṣọ́ 2000
  • Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2000
  • Ìsọ̀rí
  • ÀWỌN ẸLẸ́RÌÍ JÈHÓFÀ
  • ÀWỌN OLÙPÒKÌKÍ ÌJỌBA RÒYÌN
  • BÍBÉLÌ
  • ÌBÉÈRÈ LÁTI ỌWỌ́ ÀWỌN ÒǸKÀWÉ
  • ÌGBÉSÍ AYÉ ÀTI ÀNÍMỌ́ KRISTẸNI
  • ÌTÀN ÌGBÉSÍ AYÉ
  • JÈHÓFÀ
  • JÉSÙ KRISTI
  • LÁJORÍ ÀPILẸ̀KỌ FÚN ÌKẸ́KỌ̀Ọ́
  • Ọ̀KAN-Ò-JỌ̀KAN
Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2000
w00 12/15 ojú ìwé 31

Atọ́ka Kókó Àpilẹ̀kọ Fún Ilé Ìṣọ́ 2000

Ó ń tọ́ka sí ìtẹ̀jáde tí àpilẹ̀kọ kọ̀ọ̀kan ti jáde

ÀWỌN ẸLẸ́RÌÍ JÈHÓFÀ

A Forí Lé Àwọn Erékùṣù Pàsífíìkì—Láti Lọ Ṣiṣẹ́! 8/15

A San Èrè fún Ìwákiri Ọlọ́jọ́ Pípẹ́ (Denmark), 9/1

A Tú Ìwé Dáníẹ́lì Palẹ̀! (ìwé Àsọtẹ́lẹ̀ Dáníẹ́lì), 1/15

Altiplano ní Peru, 11/15

“Àpẹẹrẹ Ìṣọ̀kan,” 10/15

Àwọn Ìlú Olókè ní Chiapas (Mẹ́síkò), 12/15

Àwọn Tó Ṣẹ̀ṣẹ̀ Di Mẹ́ńbà Ẹgbẹ́ Olùṣàkóso, 1/1

Ayẹyẹ Ìkẹ́kọ̀ọ́yege ní Gilead, 6/15, 12/15

Bí Wọn Ò Tiẹ̀ Ga, Wọ́n Lọ́kàn Tó Dára, 2/15

Erékùṣù Robinson Crusoe, 6/15

Fífi Ìwà Ọ̀làwọ́ Hàn Lọ́pọ̀ Yanturu Ń Máyọ̀ Wá (ọrẹ), 11/1

Ìjọba Násì Ń Pọ́n Wọn Lójú (Netherlands), 4/1

Íńdíà, 5/15

Ìpàdé Àgbègbè “Àwọn Olùṣe Ohun Tí Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run Wí,” 5/1

Ìpàdé Àgbègbè “Ọ̀rọ̀ Àsọtẹ́lẹ̀ Ọlọ́run,” 1/15

Ítálì, 1/15

Kíkéde Ìjọba ní Fíjì, 9/15

Pípẹja Ènìyàn Níbi Òkun Aegean, 4/15

Senegal, 3/15

Taiwan, 7/15

Tuvalu, 12/15

ÀWỌN OLÙPÒKÌKÍ ÌJỌBA RÒYÌN

2/1, 3/1, 4/1, 5/1, 6/1, 8/1, 9/1, 12/1

BÍBÉLÌ

Àwọn Ìwé Ìhìn Rere—Ṣé Ìtàn Gidi Ni Tàbí Àròsọ? 5/15

Ǹjẹ́ Àwọn Ọ̀rọ̀ Wà Tó Jẹ́ Ẹnà? 4/1

Ọdún Tí Èyí Táa Pín Kiri Pọ̀ Jù Lọ, 1/15

Ṣé Ìwé Tó Kàn Dára Ni? 12/1

ÌBÉÈRÈ LÁTI ỌWỌ́ ÀWỌN ÒǸKÀWÉ

Àwọn oògùn tí a mú jáde láti inú ẹ̀jẹ̀, 6/15

Ẹ̀jẹ̀ ara ẹni, 10/15

Ìrunú ta ni? (Ro 12:19), 3/15

Jèhófà ní inú dídùn sí títẹ Kristi rẹ́ kẹ̀? (Isa 53:10), 8/15

Kíkọ̀ láti tẹ́wọ́ gba ìgbésẹ̀ ìkọ̀sílẹ̀, 12/15

Ta ló ṣàròyé nípa òróró tẹ́nì kan dà sí Jésù lórí? 4/15

ÌGBÉSÍ AYÉ ÀTI ÀNÍMỌ́ KRISTẸNI

Àwọn Àpẹẹrẹ Rere—Jàǹfààní Lára Wọn, 7/1

Àwọn Ìgbéyàwó Aláyọ̀ Tí Ń Bọlá fún Jèhófà, 5/1

Báwo Lo Ṣe Ń Yanjú Aáwọ̀? 8/15

Dídámọ̀ràn Ara Rẹ Fáwọn Ẹlòmíràn, 4/15

Èé Ṣe Tó Fi Yẹ Ká Ní Ẹ̀mí Ìfara-Ẹni-Rúbọ? 9/15

Ẹ̀yin Kristẹni Olùṣọ́ Àgùntàn, ‘Ẹ Jẹ́ Kí Ọkàn-Àyà Yín Gbòòrò’! 7/1

Fi Ẹ̀mí Ìmúratán Sin Ọlọ́run, 11/15

“Fi Ìṣọ́ Ṣọ́ Ọkàn-Àyà Rẹ” (Òwe 4), 5/15

Fífi Ẹ̀mí Mímọ́ Ṣe Olùrànlọ́wọ́ Ara Ẹni, 10/15

Fífi Ọkàn-Àyà Táa Ti Múra Sílẹ̀ Wá Jèhófà, 3/1

Ìfojúsọ́nà Tó Mọ Níwọ̀n, 8/1

Ìmẹ̀tọ́mọ̀wà Ń Gbé Àlàáfíà Lárugẹ, 3/15

Ìmọ̀ràn Ọlọgbọ́n Látọ̀dọ̀ Ìyá Kan (Òwe 31), 2/1

Ìtùnú Nínú Okun Jèhófà, 4/15

Jẹ́ Oníwà Mímọ́ Nínú Ayé Oníṣekúṣe (Òwe 5), 7/15

Kí Ló Dé Tí Wọn Kò Bímọ? 8/1

Kí Lo Fi Ń Díwọ̀n Àṣeyọrí? 11/1

Kí Ló Ń Mú Ọ Sin Ọlọ́run? 12/15

Kí Ni Jíjẹ́ Kristẹni Túmọ̀ Sí? 6/1

Kòṣeémánìí Lètò Àjọ Jèhófà, 1/1

Má Ba Ara Rẹ Lórúkọ Jẹ́ (Òwe 6), 9/15

Ní Ìbárẹ́ Tímọ́tímọ́ Pẹ̀lú Jèhófà (Òwe 3), 1/15

O Ha Jẹ́ Olóye Bí? 10/1

Ojú Wo Lo Fi Ń Wo Ara Rẹ? 1/15

Orin Tí Ń Múnú Ọlọ́run Dùn, 6/1

Ọ̀wọ̀ Fáwọn Aláṣẹ, 8/1

‘Pa Àwọn Àṣẹ Mọ́ Kí O sì Máa Bá A Lọ Ní Wíwà Láàyè’ (Òwe 7), 11/15

Sísún Mọ́ Ọlọ́run, 10/15

Ṣé O Ti Di “Géńdé” Kristẹni? 8/15

Ṣé Ojú Tí Ọlọ́run Fi Ń Wo Àwọn Oníwà Ipá Lo Fi Ń Wò Wọ́n? 4/15

ÌTÀN ÌGBÉSÍ AYÉ

Àìwalé-Ayé-Máyà Ló Jẹ́ Kí N Lè Sin Jèhófà (C. Moyer), 3/1

Atànmọ́lẹ̀ fún Ọ̀pọ̀ Orílẹ̀-Èdè (G. Young), 7/1

Dídúpẹ́ Lọ́wọ́ Jèhófà—Nípa Ṣíṣe Iṣẹ́ Ìsìn Alákòókò Kíkún! (S. Reynolds), 5/1

“Ẹ Kan Sáárá sí Ìgbàgbọ́ Kan Tí Kì Í Yẹ̀”! (H. Müller), 11/1

“Ẹ Kò Mọ Ohun Tí Ìwàláàyè Yín Yóò Jẹ́ Lọ́la” (H. Jennings), 12/1

Jèhófà Máa Ń San Èrè fún Àwọn Ìránṣẹ́ Rẹ̀ Adúróṣinṣin (V. Duncombe), 9/1

Jèhófà Ni Ààbò àti Okun Mi (M. Filteau), 2/1

Mo Rí Ogún Àkànṣe Gbà (C. Allen), 10/1

Olùṣe Ohun Ìjà Tẹ́lẹ̀ Wá Di Olùgba Ẹ̀mí Là (I. Ismailidis), 8/1

Ó Ràn Mí Lọ́wọ́ Láti Borí Ìtìjú (R. Ulrich), 6/1

Rírántí Ẹlẹ́dàá Láti Ìgbà Èwe (D. Hibshman), 1/1

JÈHÓFÀ

Báwo Lo Ṣe Fẹ́ Kí Ó Rántí Rẹ? 2/1

Máa Ń Gbọ́ Àdúrà, 3/1

Tóbi Ju Ọkàn-Àyà Wa Lọ, 5/1

JÉSÙ KRISTI

Bí Jésù Kristi Ṣe Lè Ràn Wá Lọ́wọ́, 3/15

LÁJORÍ ÀPILẸ̀KỌ FÚN ÌKẸ́KỌ̀Ọ́

“Arákùnrin Ni Gbogbo Yín,” 6/15

Àwọn Ẹbọ Ìyìn Tí Inú Jèhófà Dùn Sí, 8/15

Àwọn Ẹbọ Tí Inú Ọlọ́run Dùn Sí, 8/15

“Àwọn Ohun Fífani-Lọ́kàn-Mọ́ra” Ń Kún Ilé Jèhófà, 1/15

Àwọn Tí Ń Bá Ọlọ́run Jà Kò Ní Borí, 4/1

Àwọn Wo Ni Òjíṣẹ́ Ọlọ́run Lóde Òní? 11/15

Ayé Tuntun Náà—Ṣé Wàá Wà Níbẹ̀? 4/15

Báwo Ni Àkókò Tó Ṣẹ́ Kù fún Àwọn Olubi Ti Pọ̀ Tó? 2/1

Bíbá Olùṣọ́ Náà Ṣiṣẹ́ Pọ̀, 1/1

Bíbélì Kíkà—Ó Lérè, Ó sì Gbádùn Mọ́ni, 10/1

Bí Jèhófà Ṣe Ń Ṣamọ̀nà Wa, 3/15

Di Ẹ̀kọ́ Ọlọ́run Mú Gírígírí, 5/1

Ẹ Dúró Lọ́nà Pípé Pẹ̀lú Ìgbàgbọ́ Tó Fìdí Múlẹ̀, 12/15

Ẹ Fi Ẹ̀mí Ìdúródeni Hàn! 9/1

“Ẹ Máa Bá A Nìṣó Ní Ṣíṣọ́nà,” 1/15

Ẹ Máa Bọlá fún Àwọn Tó Ní Ọlá Àṣẹ Lórí Yín, 6/15

“Ẹ Máa Wá Jèhófà àti Okun Rẹ̀,” 3/1

Ẹ Ní Ẹ̀mí Ìrònú Kristi, 9/1

Ẹ Ní Ìgbàgbọ́ Nínú Ọ̀rọ̀ Àsọtẹ́lẹ̀ Ọlọ́run! 5/15

“Ẹni Tí Ó Kéré” Ti Di “Ẹgbẹ̀rún,” 1/1

Fífúnrúgbìn Òtítọ́ Ìjọba Náà, 7/1

‘Gba Ara Rẹ Àtàwọn Tí Ń Fetí sí Ọ Là,’ 6/1

Gbọ́ Ohun Tí Ẹ̀mí Ní Í Sọ, 5/1

Ìjọba Ọlọ́run—Ìṣàkóso Tuntun fún Ilẹ̀ Ayé, 10/15

Ìkùgbù Máa Ń Fa Àbùkù, 8/1

Ìrètí Àjíǹde Dájú! 7/15

Ìrètí Àjíǹde Lágbára, 7/15

Iṣẹ́ Ìsìn Ń Fún Àwọn Kristẹni Láyọ̀, 11/15

Jèhófà—Alágbára Ńlá, 3/1

Jèhófà Kò Ní Fi Nǹkan Falẹ̀, 2/1

Jèhófà Ń Fi Agbára fún Ẹni Tó Ti Rẹ̀, 12/1

Jẹ́ Kí “Ìrètí Ìgbàlà” Wà Lọ́kàn Rẹ Digbí! 6/1

Kíkẹ́kọ̀ọ́—Ó Ṣàǹfààní, Ó sì Gbádùn Mọ́ni, 10/1

Kíkún fún Ìdùnnú Nínú Ọlọ́run Ìgbàlà Wa, 2/1

Máa Fi Ìháragàgà Polongo Ìhìn Rere Náà, 7/1

Máa Fiyè sí Ọ̀rọ̀ Àsọtẹ́lẹ̀ Ọlọ́run, 4/1

Máa Fiyè sí Ọ̀rọ̀ Àsọtẹ́lẹ̀ Ọlọ́run fún Ọjọ́ Wa, 5/15

Mímọ “Èrò Inú Kristi,” 2/15

Ǹjẹ́ A Sún Ọ Láti Ṣe Bíi Ti Jésù? 2/15

Ǹjẹ́ O Ní “Èrò Inú Kristi”? 2/15

Ǹjẹ́ O Nífẹ̀ẹ́ Àwọn Ìránnilétí Jèhófà Lọ́nà Tó Kọyọyọ? 12/1

Ogún Wa Ṣíṣeyebíye—Kí Ló Túmọ̀ sí fún Ọ? 9/1

Ohun Tí Ìjọba Ọlọ́run Yóò Ṣe, 10/15

Ojú Tí Ọlọ́run Fi Ń Wo Ìwà Mímọ́, 11/1

O Lè Máa Bá Híhùwà Mímọ́ Nìṣó, 11/1

“Ọgbọ́n Wà Pẹ̀lú Àwọn Amẹ̀tọ́mọ̀wà,” 8/1

‘Ọlọ́run, Rán Ìmọ́lẹ̀ Rẹ Jáde,’ 3/15

Ran Àwọn Ẹlòmíràn Lọ́wọ́ Láti Rìn Lọ́nà Tó Yẹ Jèhófà, 12/15

Ríra Àkókò Padà Láti Kàwé àti Láti Kẹ́kọ̀ọ́, 10/1

Sísọ Ohun Gbogbo Di Tuntun—Bí A Ti Sọ Ọ́ Tẹ́lẹ̀, 4/15

“Wákàtí Náà Ti Dé!” 9/15

“Wákàtí Rẹ̀ Kò Tíì Dé,” 9/15

Ọ̀KAN-Ò-JỌ̀KAN

Àjẹ́ Ṣíṣe, 4/1

Àlàáfíà Ayé—Lọ́nà Wo? 11/1

Áńtíókù (Síríà), 7/15

Àṣírí Àṣeyọrí, 2/1

“Àwọn Àkókò Ìmúpadàbọ̀sípò” Ti Kù sí Dẹ̀dẹ̀! 9/1

Àwọn Alárìíwísí, 7/15

“Àwọn Ará ní Poland,” 1/1

Àwọn Ohun Tí Wọ́n Rí ní Jésíréélì, 3/1

Ayé Téèyàn Ò Ti Ní Bọ́hùn Mọ́, 9/15

Bí Ẹ̀mí Ṣe Ń Ṣiṣẹ́ Lónìí, 4/1

Bí O Ṣe Lè Ní Ọ̀rẹ́, 12/1

Cyril Lucaris—Ọkùnrin Tó Mọyì Bíbélì, 2/15

Èé Ṣe Tó Fi Yẹ Ká Borí Ẹ̀mí Ìṣefínnífínní Dóríi Bíńtín? 6/15

“Ewúrẹ́ Olóòfà Ẹwà Ti Orí Òkè Ńlá,” 10/1

Ẹwà Inú Lọ́hùn-ún, 11/15

Gbígbógun Ti Ìwà Ìbàjẹ́, 5/1

Ibi Tóo Ti Lè Rí Ìmọ̀ràn Rere Gbà, 6/1

Igi Ólífì, 5/15

Ìgbàgbọ́ Lè Yí Ìgbésí Ayé Rẹ Padà, 1/1

Ìgbésí Ayé Lè Túbọ̀ Nítumọ̀, 7/15

Ìkórìíra, Dópin Kẹ̀? 8/15

Ìṣọ̀kan Ìsìn Ha Sún Mọ́lé Bí? 12/1

Ìwàláàyè Lẹ́yìn Ikú, 10/1

Ìwàláàyè Pípé—Kì Í Màá Ṣe Àlá Lásán! 6/15

Jòsáyà, 9/15

Kíkẹ́kọ̀ọ́ Lára Tọkọtaya Ẹ̀dá Ènìyàn Àkọ́kọ́, 11/15

Máa Kọbi Ara sí Ìkìlọ̀! 2/15

Ǹjẹ́ Àṣà Kérésìmesì Bá Ìsìn Kristẹni Mu? 12/15

Ǹjẹ́ Ìwà Rere Tí Bíbélì Fi Kọ́ni Ṣeé Fi Sílò? 11/1

Ǹjẹ́ O Máa Ń Gba Ohun Tí O Kò Lè Rí Gbọ́? 6/15

Ǹjẹ́ O Mọ Bí A Ṣe Ń Dúró De Nǹkan? 9/1

Ǹjẹ́ Ó Tiẹ̀ Láǹfààní Tádùúrà Gbígbà Ń Ṣe? 11/15

Onínúnibíni Rí Ìmọ́lẹ̀ Ńlá (Pọ́ọ̀lù), 1/15

Ọkùnrin Àwòfiṣàpẹẹrẹ Kan Tó Tẹ́wọ́ Gba Ìbáwí (Jóòbù), 3/15

Ọlọ́run Máa Ń Gbọ́ Àdúrà, 3/1

“Rìn Yí Ká Pẹpẹ Rẹ,” 5/1

Rírí Ìbàlẹ̀ Ọkàn, 7/1

Ṣàyẹ̀wò Àwọn Ẹ̀sìn Mìíràn Kẹ̀? 10/15

Ṣé Dandan Ni Kí O Gbà Á Gbọ́? 12/1

Ṣíṣiṣẹ́ Nínú “Pápá”—Ṣáájú Ìkórè, 10/15

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́