ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • w08 8/15 ojú ìwé 1-2
  • Àwọn Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Yìí

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Àwọn Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Yìí
  • Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2008
  • Ìsọ̀rí
  • ÀWỌN ÀPILẸ̀KỌ TÁ A MÁA KẸ́KỌ̀Ọ́ NÍ Ọ̀SẸ̀:
  • Ohun Táwọn Àpilẹ̀kọ Tá a Máa Kẹ́kọ̀ọ́ Dá Lé
  • ÀWỌN ÀPILẸ̀KỌ MÍÌ NÍNÚ ÌTẸ̀JÁDE YÌÍ:
Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2008
w08 8/15 ojú ìwé 1-2

Àwọn Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Yìí

August 15, 2008

Ẹ̀dà Tó Wà Fún Ìkẹ́kọ̀ọ́

ÀWỌN ÀPILẸ̀KỌ TÁ A MÁA KẸ́KỌ̀Ọ́ NÍ Ọ̀SẸ̀:

September 29–October 5

Jèhófà Kì Yóò Fi Àwọn Ẹni Ìdúróṣinṣin Rẹ̀ Sílẹ̀

OJÚ ÌWÉ 3

ÀWỌN ORIN TÁ A Ó KỌ: 114, 223

October 6-12

Máa Bá A Nìṣó Láti Jẹ́ Adúróṣinṣin Pẹ̀lú Ọkàn Tó Ṣọ̀kan

OJÚ ÌWÉ 7

ÀWỌN ORIN TÁ A Ó KỌ: 38, 8

October 13-19

Máa Ṣe Ohun Tó Ń Gbé Iyì Jèhófà Yọ

OJÚ ÌWÉ 12

ÀWỌN ORIN TÁ A Ó KỌ: 48, 136

October 20-26

Jèhófà Ń Ṣìkẹ́ Àwọn Ìránṣẹ́ Rẹ̀ Tó Jẹ́ Àgbàlagbà

OJÚ ÌWÉ 17

ÀWỌN ORIN TÁ A Ó KỌ: 58, 216

October 27–November 2

Ǹjẹ́ Ò Ń Sọ “Èdè Mímọ́” Lọ́nà Tó Já Geere?

OJÚ ÌWÉ 21

ÀWỌN ORIN TÁ A Ó KỌ: 78, 169

Ohun Táwọn Àpilẹ̀kọ Tá a Máa Kẹ́kọ̀ọ́ Dá Lé

Àpilẹ̀kọ fún Ìkẹ́kọ̀ọ́ 1 àti 2 OJÚ ÌWÉ 3 sí 11

Àpilẹ̀kọ yìí fi hàn pé Jèhófà kò fàwọn ẹni ìdúróṣinṣin rẹ̀ sílẹ̀ nígbà tí orílẹ̀-èdè Ísírẹ́lì pín sí abẹ́ ìjọba méjì ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀, ti àríwá àti gúúsù. Àpilẹ̀kọ yìí tẹnu mọ́ ọn pé ó ṣe pàtàkì pé ká jẹ́ adúróṣinṣin látọkànwá nísinsìnyí ká má bàa ṣubú sínú ìdẹkùn ìfẹ́ ọrọ̀ tàbí híhùwà ọ̀yájú.

Àpilẹ̀kọ fún Ìkẹ́kọ̀ọ́ 3 OJÚ ÌWÉ 12 sí 16

Àpilẹ̀kọ yìí sọ bó ṣe yẹ ká máa ṣe torí bá a ṣe mọyì ògo Ọlọ́run. Ó ṣàlàyé ẹ̀kọ́ tá a máa kọ́ nípa bíbuyì kúnni nínú ọ̀nà tí Jésù gbà hùwà sáwọn èèyàn. Wàá tún kọ́ nípa bá a ṣe lè hùwà tó buyì kúnni.

Àpilẹ̀kọ fún Ìkẹ́kọ̀ọ́ 4 OJÚ ÌWÉ 17 sí 21

Kẹ́kọ̀ọ́ nípa bá a ṣe lè máa wo àwọn Kristẹni tó jẹ́ àgbàlagbà gẹ́gẹ́ bí Jèhófà ṣe ń wò wọ́n. Ṣàkíyèsí bí Bíbélì ṣe jẹ́ ká mọ bó ṣe yẹ ká bọ̀wọ̀ fún wọn nítorí ìmọ̀ àti ìrírí wọn, ká máa kíyè sí bí nǹkan ṣe máa ń rí lára wọn, ká sì máa tì wọ́n lẹ́yìn kí wọ́n lè máa bá iṣẹ́ ìsìn wọn lọ.

Àpilẹ̀kọ fún Ìkẹ́kọ̀ọ́ 5 OJÚ ÌWÉ 21 sí 25

Jèhófà sọ nípasẹ̀ Sefanáyà wòlíì rẹ̀ pé: “Èmi yóò fún àwọn ènìyàn ní ìyípadà sí èdè mímọ́.” (Sef. 3:9) Kẹ́kọ̀ọ́ nípa ohun tó ń jẹ́ “èdè mímọ́.” Wo àwọn ohun tó o lè ṣe kó o bàa lè mọ̀ ọ́n sọ dáadáa. Kó o sì wá rí bó o ṣe lè máa lo èdè tí ò láfiwé yìí láti fi yin Jèhófà.

ÀWỌN ÀPILẸ̀KỌ MÍÌ NÍNÚ ÌTẸ̀JÁDE YÌÍ:

Ọ̀rọ̀ Jèhófà Yè—Àwọn Kókó Pàtàkì Látinú Ìwé Gálátíà, Éfésù, Fílípì àti Kólósè

OJÚ ÌWÉ 26

Ǹjẹ́ O Rántí?

OJÚ ÌWÉ 29

Àwọn Míṣọ́nnárì Dà Bí Eéṣú

OJÚ ÌWÉ 30

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́