ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • w08 10/15 ojú ìwé 1-2
  • Àwọn Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Yìí

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Àwọn Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Yìí
  • Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2008
  • Ìsọ̀rí
  • ÀWỌN ÀPILẸ̀KỌ TÁ A MÁA KẸ́KỌ̀Ọ́ NÍ Ọ̀SẸ̀:
  • Ohun Táwọn Àpilẹ̀kọ Tá a Máa Kẹ́kọ̀ọ́ Dá Lé
  • ÀWỌN ÀPILẸ̀KỌ MÍÌ NÍNÚ ÌTẸ̀JÁDE YÌÍ:
Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2008
w08 10/15 ojú ìwé 1-2

Àwọn Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Yìí

October 15, 2008

Ẹ̀dà Tó Wà Fún Ìkẹ́kọ̀ọ́

ÀWỌN ÀPILẸ̀KỌ TÁ A MÁA KẸ́KỌ̀Ọ́ NÍ Ọ̀SẸ̀:

December 1-7

Ojú Jèhófà “Títàn Yanran” Ń Ṣàyẹ̀wò Gbogbo Èèyàn

OJÚ ÌWÉ 3

ÀWỌN ORIN TÁ A Ó KỌ: 160, 34

December 8-14

Jèhófà Ń Ṣọ́ Wa fún Ire Wa

OJÚ ÌWÉ 7

ÀWỌN ORIN TÁ A Ó KỌ: 81, 80

December 15-21

Jèhófà Dáhùn Àdúrà Àtọkànwá Tí Ìránṣẹ́ Rẹ̀ Kan Gbà

OJÚ ÌWÉ 12

ÀWỌN ORIN TÁ A Ó KỌ: 74, 90

December 22-28

Ṣé O Ń Mú Ipò Iwájú Nínú Bíbu Ọlá Fáwọn Èèyàn?

OJÚ ÌWÉ 21

ÀWỌN ORIN TÁ A Ó KỌ: 216, 155

December 29–January 4

Kí Lo Máa Yááfì Kó O Lè Ní Ìyè Àìnípẹ̀kun?

OJÚ ÌWÉ 25

ÀWỌN ORIN TÁ A Ó KỌ: 177, 212

Ohun Táwọn Àpilẹ̀kọ Tá a Máa Kẹ́kọ̀ọ́ Dá Lé

Àpilẹ̀kọ fún Ìkẹ́kọ̀ọ́ 1 àti 2 OJÚ ÌWÉ 3 sí 11

Àpilẹ̀kọ méjèèjì yìí mú un dá wa lójú pé Jèhófà mọ gbogbo ohun tó ń ṣẹlẹ̀ sí wa. Ó mọrírì ìfaradà wa, ó sì mọ ohun tó ń jẹ wá lọ́kàn. Ó mọ gbogbo iṣẹ́ takuntakun tá à ń ṣe, kò sì sóhun tó ń ṣẹlẹ̀ sáwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ tó fara sin lójú rẹ̀. Èyí jẹ́ ohun tó ń tù wá nínú gan-an ni.

Àpilẹ̀kọ fún Ìkẹ́kọ̀ọ́ 3 OJÚ ÌWÉ 12 sí 16

Ó fẹ́rẹ̀ẹ́ jẹ́ pé gbogbo wa la mọ ọ̀rọ̀ tó wà nínú Sáàmù 83:18. Àmọ́ àwọn ẹsẹ tó kù ńkọ́? Àpilẹ̀kọ yìí jẹ́ ká mọ bí Sáàmù 83 ṣe fún àwa Kristẹni òde òní ní ìṣírí gidigidi.

Àpilẹ̀kọ fún Ìkẹ́kọ̀ọ́ 4 OJÚ ÌWÉ 21 sí 25

Pọ́ọ̀lù sọ pé: “Nínú bíbu ọlá fún ara yín lẹ́nì kìíní-kejì, ẹ mú ipò iwájú.” Kí ló túmọ̀ sí láti máa bọlá fáwọn èèyàn? Àwọn wo ló yẹ kó máa bọlá fúnni, àwọn wo ló sì yẹ ká máa bọlá fún? Àwọn àpẹẹrẹ wo ló wà nínú Bíbélì tó bá dọ̀rọ̀ ká bọlá fúnni? Àpilẹ̀kọ yìí jíròrò àwọn ẹ̀kọ́ tó yẹ ká máa fi sílò lórí ọ̀ràn bíbọlá fúnni.

Àpilẹ̀kọ fún Ìkẹ́kọ̀ọ́ 5 OJÚ ÌWÉ 25 sí 29

Lọ́jọ́ kan Jésù béèrè pé: “Kí ni ènìyàn kan yóò fi fúnni ní pàṣípààrọ̀ fún ọkàn rẹ̀?” Báwo lo ṣe máa dáhùn ìbéèrè yẹn? “Ọkàn” wo ni Jésù ń tọ́ka sí? Kí ni ọ̀nà tó ò ń gbà gbé ìgbé ayé rẹ fi hàn nípa bó o ṣe mọyì ọkàn rẹ sí? Àpilẹ̀kọ yìí máa jẹ́ kó o lè ṣàṣàrò dáadáa lórí àwọn ìbéèrè Jésù tó gba ìrònújinlẹ̀ yẹn.

ÀWỌN ÀPILẸ̀KỌ MÍÌ NÍNÚ ÌTẸ̀JÁDE YÌÍ:

“Orúkọ Ọlọ́run Tó Tóbi Tó sì Jẹ́ Mímọ́ Jù Lọ Rèé Lóòótọ́”

OJÚ ÌWÉ 16

“Jèhófà Ni Okun Mi”

OJÚ ÌWÉ 17

Ọ̀rọ̀ Jèhófà Yè—Àwọn Kókó Pàtàkì Látinú Ìwé Títù, Fílémónì àti Hébérù

OJÚ ÌWÉ 30

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́