ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • w10 5/15 ojú ìwé 1-2
  • Àwọn Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Yìí

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Àwọn Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Yìí
  • Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2010
  • Ìsọ̀rí
  • ÀWỌN ÀPILẸ̀KỌ TÁ A MÁA KẸ́KỌ̀Ọ́ NÍ Ọ̀SẸ̀:
  • Ohun Táwọn Àpilẹ̀kọ Tá a Máa Kẹ́kọ̀ọ́ Dá Lé
  • ÀWỌN ÀPILẸ̀KỌ MÍÌ NÍNÚ ÌTẸ̀JÁDE YÌÍ:
Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2010
w10 5/15 ojú ìwé 1-2

Àwọn Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Yìí

May 15, 2010

Ẹ̀dà Tó Wà Fún Ìkẹ́kọ̀ọ́

ÀWỌN ÀPILẸ̀KỌ TÁ A MÁA KẸ́KỌ̀Ọ́ NÍ Ọ̀SẸ̀:

June 28–July 4

Ẹ̀yin Ọkùnrin, Ṣé Ẹ̀ Ń Tẹrí Ba fún Ipò Orí Kristi?

OJÚ ÌWÉ 8

ÀWỌN ORIN TÁ A Ó KỌ: 5, 123

July 5-11

Ẹ̀yin Obìnrin, Kí Nìdí Tó Fi Yẹ Kẹ́ Ẹ Máa Tẹrí Ba fún Ipò Orí?

OJÚ ÌWÉ 12

ÀWỌN ORIN TÁ A Ó KỌ: 86, 120

July 12-18

Ẹ̀yin Arákùnrin, Ẹ Fúnrúgbìn Nípa Tẹ̀mí, Kẹ́ Ẹ sì Máa Wá Àǹfààní Iṣẹ́ Ìsìn!

OJÚ ÌWÉ 24

ÀWỌN ORIN TÁ A Ó KỌ: 45, 11

July 19-25

Ẹ Má Ṣe Kó Ẹ̀dùn-Ọkàn Bá Ẹ̀mí Mímọ́ Jèhófà

OJÚ ÌWÉ 28

ÀWỌN ORIN TÁ A Ó KỌ: 71, 26

Ohun Táwọn Àpilẹ̀kọ Tá a Máa Kẹ́kọ̀ọ́ Dá Lé

ÀPILẸ̀KỌ FÚN ÌKẸ́KỌ̀Ọ́ 1 ÀTI 2 OJÚ ÌWÉ 8 SÍ 17 ▴

Àpilẹ̀kọ àkọ́kọ́ sọ bó ti ṣe pàtàkì tó fún àwọn arákùnrin láti máa tẹrí ba fún ẹni tí í ṣe Orí wọn, ìyẹn Kristi, kí wọ́n sì máa tẹ̀ lé àpẹẹrẹ rẹ̀ nínú ọ̀nà tí wọ́n gbà ń bá àwọn ẹlòmíì lò. Àpilẹ̀kọ kejì ṣàlàyé ojú tí àwọn arábìnrin gbọ́dọ̀ máa fi wo gbólóhùn náà: “Orí obìnrin ni ọkùnrin.”

ÀPILẸ̀KỌ FÚN ÌKẸ́KỌ̀Ọ́ 3 ÀTI 4 OJÚ ÌWÉ 24 SÍ 32

Lóde òní, ọ̀pọ̀ èèyàn ò fi bẹ́ẹ̀ gba ti pé kí wọ́n máa yááfì àwọn nǹkan nítorí àwọn ẹlòmíì mọ́. A dìídì ṣe àpilẹ̀kọ àkọ́kọ́ lọ́nà tí yóò fi lè ran àwọn ọkùnrin tó ti ṣèrìbọmi lọ́wọ́ láti ṣàgbéyẹ̀wò ojú tí wọ́n fi ń wo ìfara-ẹni-rúbọ àti títẹ́wọ́ gba ojúṣe láti sìn gẹ́gẹ́ bí ìránṣẹ́ iṣẹ́ òjíṣẹ́ tàbí alàgbà. Àpilẹ̀kọ kejì ṣàlàyé bí a kò ṣe ní máa mú ẹ̀mí mímọ́ Ọlọ́run bínú.

ÀWỌN ÀPILẸ̀KỌ MÍÌ NÍNÚ ÌTẸ̀JÁDE YÌÍ:

Ojú Tí Àwọn Kristẹni Ọ̀rúndún Kìíní Fi Wo Òrìṣà Àwọn Ará Róòmù 3

Kí Nìdí Tó Fi Yẹ Ká Máa Bọ̀wọ̀ fún Àwọn Àgbàlagbà? 6

Má Ṣe Jẹ́ Kí Ohunkóhun Pa Àjọṣe Rẹ Pẹ̀lú Ọlọ́run Lára Bó O Bá Ń Tọ́jú Ìbátan Rẹ Tó Ń Ṣàìsàn 17

Háránì Ìlú Àtijọ́ Tó Kún fún Ìgbòkègbodò 20

Ìbéèrè Láti Ọwọ́ Àwọn Òǹkàwé 21

Máa Lo Agbára Ìwòye Rẹ 22

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́