ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • w11 1/15 ojú ìwé 1-2
  • Àwọn Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Yìí

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Àwọn Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Yìí
  • Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2011
  • Ìsọ̀rí
  • ÀWỌN ÀPILẸ̀KỌ TÁ A MÁA KẸ́KỌ̀Ọ́ NÍ Ọ̀SẸ̀:
  • Ohun Táwọn Àpilẹ̀kọ Tá A Máa Kẹ́kọ̀ọ́ Dá Lé
  • ÀWỌN ÀPILẸ̀KỌ MÍÌ NÍNÚ ÌTẸ̀JÁDE YÌÍ:
Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2011
w11 1/15 ojú ìwé 1-2

Àwọn Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Yìí

January 15, 2011

Ẹ̀dà Tó Wà Fún Ìkẹ́kọ̀ọ́

ÀWỌN ÀPILẸ̀KỌ TÁ A MÁA KẸ́KỌ̀Ọ́ NÍ Ọ̀SẸ̀:

February 28, 2011–March 6, 2011

“Sá Di Orúkọ Jèhófà”

OJÚ ÌWÉ 3

ÀWỌN ORIN TÍ A Ó KỌ: 49, 74

March 7-13, 2011

Bọ̀wọ̀ fún Ìgbéyàwó Tó Jẹ́ Ẹ̀bùn Ọlọ́run

OJÚ ÌWÉ 13

ÀWỌN ORIN TÍ A Ó KỌ: 36, 94

March 14-20, 2011

Lo Ẹ̀bùn Wíwà Láìní Ọkọ Tàbí Aya Lọ́nà Tó Dára Jù Lọ

OJÚ ÌWÉ 17

ÀWỌN ORIN TÍ A Ó KỌ: 85, 121

March 21-27, 2011

Ẹ̀mí Mímọ́ Ń Fún Wa Lágbára Ká Lè Kojú Ìdẹwò Ká sì Borí Ìrẹ̀wẹ̀sì

OJÚ ÌWÉ 22

ÀWỌN ORIN TÍ A Ó KỌ: 81, 17

March 28, 2011–April 3, 2011

Ẹ̀mí Mímọ́ Ń Fún Wa Lágbára Ká Lè Borí Àdánwò Èyíkéyìí

OJÚ ÌWÉ 26

ÀWỌN ORIN TÍ A Ó KỌ: 133, 100

Ohun Táwọn Àpilẹ̀kọ Tá A Máa Kẹ́kọ̀ọ́ Dá Lé

ÀPILẸ̀KỌ FÚN ÌKẸ́KỌ̀Ọ́ 1 OJÚ ÌWÉ 3 sí 7

Ibo la ti lè rí ààbò ní àkókò lílekoko tá à ń gbé yìí? Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run ṣàlàyé pé a lè fi orúkọ Jèhófà ṣe ibi ìsádi wa. Àpilẹ̀kọ yìí jíròrò bí a ṣe lè rí ààbò nísinsìnyí àti ní ìgbà tí “ọjọ́ ńlá Jèhófà” bá dé. Àpilẹ̀kọ náà dá lórí ẹsẹ Ìwé Mímọ́ ọdún 2011.

ÀPILẸ̀KỌ FÚN ÌKẸ́KỌ̀Ọ́ 2 àti 3 OJÚ ÌWÉ 13 sí 21

Ìgbéyàwó àti wíwà láìṣègbéyàwó jẹ́ ẹ̀bùn látọ̀dọ̀ Ọlọ́run, ọ̀kọ̀ọ̀kan wọn sì ní àǹfààní tirẹ̀. Yálà a ti ṣègbéyàwó tàbí a kò tíì ṣègbéyàwó, ohun tá a jíròrò nínú àwọn àpilẹ̀kọ yìí á jẹ́ ká rí ìdí tó fi yẹ ká mọyì àwọn ẹ̀bùn méjèèjì náà, ó sì máa ṣàlàyé ọ̀nà tá a lè gbà fi hàn pé a mọyì wọn fún wa.

ÀPILẸ̀KỌ FÚN ÌKẸ́KỌ̀Ọ́ 4 àti 5 OJÚ ÌWÉ 22 sí 30

Ká bàa lè mú ẹ̀jẹ́ ìyàsímímọ́ wa ṣẹ, a nílò ìrànlọ́wọ́ Jèhófà. Nínú àwọn àpilẹ̀kọ yìí, a jíròrò bí ẹ̀mí mímọ́ ṣe lè ràn wá lọ́wọ́ ká lè kojú ìdẹwò, ká borí ìrẹ̀wẹ̀sì, ká fara da inúnibíni, ká dènà ẹ̀mí ṣohun-tẹ́gbẹ́-ń-ṣe, ká sì fara da ìpọ́njú.

ÀWỌN ÀPILẸ̀KỌ MÍÌ NÍNÚ ÌTẸ̀JÁDE YÌÍ:

7 A Rí Orúkọ Ọlọ́run Níbi Àfonífojì

9 Mo Dúpẹ́ Pé Àdánwò Kò Mú Kí N Dẹ́kun Láti Máa Sin Jèhófà

31 Máa Ṣe Àṣàrò Lórí Ohun tí Jèhófà Ti Ṣe fún Ẹ

[Àwòrán Credit Line tó wà ní ojú ìwé 2]

© Stähli Rolf A/age fotostock

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́